< Jeremia 33 >

1 Kane pod Jeremia oketi e agola kamane irite, wach Jehova Nyasaye nobirone mar ariyo ni:
Nígbà tí Jeremiah wà nínú àgbàlá túbú, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ọ́ wá lẹ́ẹ̀kejì:
2 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho, en ema nochweyo piny, Jehova Nyasaye mane olose kendo oketo mise mare, Jehova Nyasaye e nyinge:
“Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ẹni tí ó dá ayé, Olúwa tí ó mọ ayé tí ó sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, Olúwa ni orúkọ rẹ̀:
3 ‘Bi ira, kendo anaduoki, kendo ananyisi gik madongo ma ok ingʼeyo.’
‘Pè mí, èmi ó sì dá ọ lóhùn, èmi ó sì sọ ohun alágbára ńlá àti ọ̀pọ̀ ohun tí kò ṣe é wádìí tí ìwọ kò mọ̀ fún ọ.’
4 Nimar ma e gima Jehova Nyasaye, Nyasach Israel, wacho kuom ute manie dala maduongʼni kod kuonde dak mar ruodh Juda ma osemuki mondo tigo kaka pidhe kod ligangla
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ nípa àwọn ilẹ̀ ìlú yìí àti ààfin àwọn ọba Juda tí ó ti wó lulẹ̀ nítorí àwọn ìdọ̀tí àti idà
5 kuom kedo gi jo-Babulon: ‘Ginipongʼ-gi gi ringre joma otho mabiro nego gi ich wangʼ mara kod mirimba. Anapand wangʼa ne dala maduongʼni nikech timbegi duto mamono.
nínú ìjà pẹ̀lú Kaldea: ‘Wọn yóò kún fún ọ̀pọ̀ òkú ọmọkùnrin tí èmi yóò pa nínú ìbínú àti nínú ìrunú mi. Èmi ó pa ojú mi mọ́ kúrò ní ìlú yìí nítorí gbogbo búburú wọn.
6 “‘Kata kamano, anamigi ngima kendo chang; anachang joga kendo anami gibed gi mor kuom kwe mathoth kod rit mogundho.
“‘Wò ó, èmi ó mú ọ̀já àti oògùn ìmúláradá dì í; èmi ó wo àwọn ènìyàn mi sàn. Èmi ó sì jẹ́ kí wọn ó jẹ ìgbádùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀ àlàáfíà àti òtítọ́.
7 Anaduog Juda kod Israel koa e twech kendo analosgi gibed kaka ne gin chon.
Èmi ó mú Juda àti Israẹli kúrò nínú ìgbèkùn, èmi ó sì tún wọn kọ́ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe wà tẹ́lẹ̀.
8 Anapwodhgi kuom richo magisetimona kendo anawenegi richogi duto mag ngʼanyona.
Èmi ó wẹ̀ wọ́n nù kúrò nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ti ṣẹ sí mi. Èmi ó sì dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ àìṣedéédéé wọn sí mi jì wọ́n.
9 Eka dala maduongʼni nomi abed gihuma, ilo, pak kod luor e nyim ogendini duto manie piny mawinjo gik moko duto mabeyo masetimone; kendo ginibed gi luoro mi ginitetni kuom gweth mogundho kod kwe masechiwone.’
Nígbà náà ni ìlú yìí ó fún mi ní òkìkí, ayọ̀, ìyìn àti ọlá níwájú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé; tí wọ́n gbọ́ gbogbo rere tí èmi ṣe fún wọn. Wọn ó sì bẹ̀rù, wọn ó wárìrì fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ oore àti àlàáfíà tí èmi pèsè fún wọn.’
10 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: ‘Uwuoyo kuom dala maduongʼni niya, “Osedongʼ nono chuth, maonge ji kata jamni modakie.” Kata obedo ni mier mag Juda kod yore mag Jerusalem odongʼ nono kamano, maonge ji kata jamni modakie, to ubiro chako winjo,
“Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ‘Ẹ̀yin yóò wí nípa ibí yìí pé, “Ó dahoro, láìsí ènìyàn tàbí ẹran.” Síbẹ̀ ní ìlú Juda àti ní òpópónà Jerusalẹmu tí ó dahoro, láìsí ẹni tó gbé ibẹ̀; ìbá à se ènìyàn tàbí ẹran, tí yóò gbọ́ lẹ́ẹ̀kan sí.
11 mor gi ilo kuondego, dwond miaha kod wuon kisera, kod dwond jogo makelo chiwo mar goyo erokamano ne od Jehova Nyasaye. Negiwacho niya, “‘“Goneuru Jehova Nyasaye Maratego erokamano, nimar Jehova Nyasaye ber; herane osiko nyaka chiengʼ.” Nimar anaduog gweth ne piny mane gin-go chon,’ Jehova Nyasaye owacho.
Ariwo ayọ̀ àti inú dídùn, ohùn ìyàwó àti ti ọkọ ìyàwó àti ohùn àwọn tí ó ru ẹbọ ọpẹ́ wọn nílé Olúwa wí pé: “‘“Yin Olúwa àwọn ọmọ-ogun, nítorí Olúwa dára, ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé.” Nítorí èmi ó dá ìkólọ ilẹ̀ náà padà sí bí o ṣe wà tẹ́lẹ̀,’ ni Olúwa wí.
12 “Ma e gima Jehova Nyasaye Maratego wacho: ‘Ka eri, mamono kendo maonge ji kata le, tiende ni e dalane duto nobedi kar kwath ma jokwath kwayoe rombegi.
“Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Ní ilẹ̀ yìí tí ó ti dahoro láìsí ọkùnrin àti àwọn ẹran nínú gbogbo ìlú, kò ní sí pápá oko fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti mú àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sinmi.
13 E dala manie piny gode, mago mantie e tie gode man yo podho chiengʼ kod mago man Negev, mantiere e gwenge mag Benjamin, e mier molworo Jerusalem kod dala mag Juda, rombe nokal kendo e lwet ngʼatno ma kwanogi,’ Jehova Nyasaye owacho.
Ní ìlú òkè wọ̀n-ọn-nì, nínú ìlú àfonífojì, àti nínú ìlú ìhà gúúsù, àti ní ilẹ̀ ti Benjamini, ní ibi wọ̀n-ọn-nì tí ó yí Jerusalẹmu ká, àti ní ìlú Juda ni agbo àgùntàn yóò tún máa kọjá ní ọwọ́ ẹni tí ń kà wọ́n,’ ni Olúwa wí.
14 “‘Ndalo biro ma abiro chopo singruokna mar ngʼwono mane aloso gi od Israel kod gi od Juda,’ Jehova Nyasaye ema owacho.
“‘Àwọn ọjọ́ náà ń bọ̀,’ ni Olúwa wí, ‘tí èmi ó mú ìlérí rere tí mo ṣe fún ilé Israẹli àti ilé Juda ṣẹ.
15 “‘E ndalogo kendo e kindeno anami Bad Yath makare owuog e koth Daudi; enotim gima ratiro kendo nikare e piny.
“‘Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àti ní àkókò náà, Èmi ó gbé olódodo dìde láti ẹ̀ka Dafidi. Yóò ṣe ìdájọ́ àti ohun tí ó tọ́ ní ilẹ̀ náà.
16 E ndalogo Juda noresi kendo Jerusalem nodag gi kwe. Ma e nying ma ibiro luongego: Jehova Nyasaye mamiyo wabedo jo-ratiro.’
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Juda yóò di ẹni ìgbàlà. Jerusalẹmu yóò sì máa gbé láìséwu. Orúkọ yìí ni a ó máa pè é Olúwa wa olódodo.’
17 Nimar ma e gima Jehova Nyasaye wacho: ‘Daudi ok nobed maonge gi ngʼato manobedi e kom duongʼ mar od Israel,
Nítorí báyìí ni Olúwa wí: ‘Dafidi kò ní kùnà láti rí ọkùnrin tí yóò jókòó lórí ìtẹ́ ní ilé Israẹli.
18 kata jodolo, ma jo-Lawi, bende ok nobed maonge gi ngʼato machungʼ e nyima seche duto mar chiwo misengini miwangʼo pep, ka giwangʼo misengini mag cham kendo chiwo misengini.’”
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà tí ó jẹ́ ọmọ Lefi kò ní kùnà láti ní ọkùnrin kan tí ó dúró níwájú mi ní gbogbo ìgbà láti rú ẹbọ sísun; ẹbọ jíjẹ àti láti pèsè ìrúbọ.’”
19 Wach Jehova Nyasaye nobiro ne Jeremia:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá wí pé:
20 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: ‘Ka inyalo ketho singruokna modiechiengʼ kod singruokna motieno, mondo omi odiechiengʼ kod otieno kik bi e sechegi mowinjore,
“Èyí ni ohun tí Olúwa sọ: ‘Tí ìwọ bá lè dá májẹ̀mú mi ní òru tó bẹ́ẹ̀ tí ọ̀sán àti òru kò lè sí ní àkókò wọn mọ́.
21 bangʼe singruokna gi Daudi jatichna kod singruokna gi jo-Lawi ma gin jodolo ma yalo e nyima inyalo kethi to Daudi ok nobed gi nyakware manobed gi loch e kom duongʼ mare.
Nígbà náà ni májẹ̀mú mi pẹ̀lú Dafidi ìránṣẹ́ mi àti májẹ̀mú mi pẹ̀lú Lefi tí ó jẹ́ àlùfáà, àwọn ìránṣẹ́ níwájú mi lè bàjẹ́, tí Dafidi kò sì rí ẹni láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀.
22 Anami nyikwa Daudi jatichna kod jo-Lawi ma yalo e nyima bed mangʼeny mokalo akwana ka sulwe manie kor polo kendo ma ok nyal pim ka kwoyo manie dho nam.’”
Èmi ó mú àwọn ọmọ lẹ́yìn Dafidi ìránṣẹ́ mi àti Lefi tí ó jẹ́ oníwàásù níwájú mi di bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, tí kò ṣe é kà àti bí iyẹ̀pẹ̀ ojú Òkun tí kò ṣe é wọ́n.’”
23 Wach Jehova Nyasaye nobiro ne Jeremia:
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé:
24 “Bende isefwenyo ni jogi wachoni ni, ‘Jehova Nyasaye osekwedo dhoudi ariyo mane oyiero’? Omiyo gijaro joga kendo ok gikawo joga ka oganda achiel.
“Ǹjẹ́ ìwọ kò kíyèsi pé àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń sọ pé: ‘Olúwa ti kọ àwọn ọba méjèèjì tí ó yàn sílẹ̀’? Nítorí náà, ni wọ́n ti ṣe kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi. Wọn kò sì mọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè kan.
25 Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: ‘Ka dipo ni pod ok aketo singruokna godiechiengʼ gi otieno kod chike mogurore mar polo kod piny,
Báyìí ni Olúwa wí: ‘Bí èmi kò bá ti da májẹ̀mú mi pẹ̀lú ọ̀sán àti òru àti pẹ̀lú òfin ọ̀run àti ayé tí kò lè yẹ̀.
26 eka anakwed nyikwa Jakobo kod Daudi jatichna kendo ok anayier achiel kuom yawuote mondo obed jatelo ewi nyikwa Ibrahim, Isaka kod Jakobo. Nimar anaduognegi mwandugi mi anangʼwon-negi.’”
Nígbà náà ni èmi ó kọ ọmọ lẹ́yìn Jakọbu àti Dafidi ìránṣẹ́ mi tí èmi kò sì ní yan ọ̀kan nínú ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ́ alákòóso lórí àwọn ọmọ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu; nítorí èmi ó mú ìkólọ wọn padà; èmi ó sì ṣàánú fún wọn.’”

< Jeremia 33 >