< Jeremia 30 >

1 Ma e wach mane obirone Jeremia koa kuom Jehova Nyasaye:
Ọ̀rọ̀ tí ó tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, wí pé:
2 “Ma e gima Jehova Nyasaye, Nyasach Israel, wacho: ‘Ndik e kitabu weche duto masewachoni.’
“Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, pé: ‘Ìwọ kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti bá ọ sọ sínú ìwé kan.
3 Jehova Nyasaye wacho niya, ‘Ndalo biro ma anaduog joga Israel kod Juda koa e twech kendo achokgi e piny mane amiyo kweregi mondo okaw,’ Jehova Nyasaye owacho.”
Ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí ń ó mú àwọn ènìyàn mi, àwọn ọmọ Israẹli àti Juda kúrò nínú ìgbèkùn, tí n ó sì dá wọn padà sí orí ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn baba ńlá wọn láti ní,’ ni Olúwa Ọlọ́run wí.”
4 Magi e weche mane Jehova Nyasaye owacho kuom Israel gi Juda:
Ìwọ̀nyí ni àwọn ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run sí Israẹli àti Juda:
5 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: “‘Ywak mar luoro winjore, en bwok malich, to ok kwe.
“Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Igbe ẹ̀rù àti ìwárìrì ni a gbọ́ láìṣe igbe àlàáfíà.
6 Koro lingʼuru mondo uparane: Bende dichwo nyalo nywolo nyithindo? To kare angʼo momiyo aneno dichwo ka dichwo maratego, komako iye ka dhako mamuoch kayo, ka luoro omakogi ka joma chiegni tho?
Béèrè kí o sì rí. Ǹjẹ́ ọkùnrin le dá ọmọ bí? Èéṣe tí mo fi ń rí àwọn alágbára ọkùnrin tí wọ́n fi ọwọ́ wọn mú inú wọn bí obìnrin tó ń rọbí, tí ojú gbogbo wọ́n sì fàro fún ìrora?
7 Mano kaka odiechiengʼno nobed malich! Onge manochal kode. Enobed kinde mag chandruok ne Jakobo, to norese.’”
Ọjọ́ náà yóò ha ti burú tó! Kò sí ọjọ́ tí yóò dàbí rẹ̀, Ọjọ́ náà yóò jẹ́ àkókò ìdààmú fún Jakọbu ṣùgbọ́n yóò rí ìgbàlà kúrò nínú ìdààmú náà.
8 Jehova Nyasaye Maratego wacho niya, “‘E odiechiengʼno anatur jok manie ngʼutgi, kendo anachod nyoroche motwegigo; joma welo ok nochak oketgi wasumbini mag-gi kendo.
“‘Ní ọjọ́ náà,’ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Èmi yóò gbé àjàgà kúrò lọ́rùn wọn, Èmi yóò sì tú ìdè wọn sọnù. Àwọn àjèjì kì yóò sì mú ọ sìn wọ́n mọ́.
9 To kata kamano ginitine Jehova Nyasaye ma Nyasachgi kod Daudi ruodhgi, ma anamigi.
Dípò bẹ́ẹ̀ wọn yóò máa sin Olúwa Ọlọ́run wọn àti Dafidi gẹ́gẹ́ bí ọba wọn, ẹni tí èmi yóò gbé dìde fún wọn.
10 “‘Omiyo kik iluor, yaye Jakobo jatichna; kik ibwogi, yaye Israel,’ Jehova Nyasaye owacho. ‘Adier anaresi kia e piny mabor, in kaachiel gi nyikwayi koaye piny motwegie. Jakobo nobed gi kwe kendo norite maonge ngʼama nomiye luoro.
“‘Nítorí náà, má ṣe bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi, má sì ṣe jẹ́ kí ẹ̀rù bà ọ́, ìwọ Israẹli,’ ni Olúwa wí. ‘Èmi yóò gbà ọ́ kúrò láti ọ̀nà jíjìn wá, àní àwọn ìran rẹ láti ilẹ̀ àtìpó wọn. Jakọbu yóò sì tún ní àlàáfíà àti ààbò rẹ̀ padà, kò sì ṣí ẹni tí yóò ṣẹ̀rù bà á mọ́.
11 Anabed kodi kendo anaresi,’ Jehova Nyasaye wacho. ‘Kata obedo ni atieko chuth ogendini duto ma akeyou e diergi, ok anatieki chuth. Anakumu ka angʼadonu bura makare; ok anaweu ma ok akumou.’
Èmi wà pẹ̀lú rẹ, n ó sì gbà ọ́,’ ni Olúwa wí. ‘Bí mo tilẹ̀ pa gbogbo orílẹ̀-èdè run, nínú èyí tí mo ti fọ́n ọn yín ká, síbẹ̀ èmi kì yóò pa yín run pátápátá. Èmi yóò bá yín wí pẹ̀lú ìdájọ́ òdodo nìkan; Èmi kò ní fi yín sílẹ̀ láìjìyà.’
12 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: “‘Adhola mari ok nyal thiedhi, hinyruok mari okalo chango.
“Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Ọgbẹ́ yín kò gbóògùn, bẹ́ẹ̀ ni egbò yín kọjá ìwòsàn.
13 Onge ngʼama nyalo chiwo kwayoni kari, kendo onge gima nyalo thiedhoni adhola, kata manyalo changi.
Kò sí ẹnìkan tí yóò bẹ̀bẹ̀ fún àìṣedéédéé yín, kò sí ètùtù fún ọgbẹ́ yín, a kò sì mú yín láradá.
14 Joma ne osiepeni duto wigi osewil kodi; kendo ok gidewi. Asegoyi mana ka jasigu kendo kumi mana ka ngʼama kwiny, nikech ketho mari duongʼ kendo richoni ngʼeny.
Gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ ti gbàgbé rẹ, wọn kò sì náání rẹ mọ́ pẹ̀lú. Mo ti nà ọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀tá rẹ yóò ti nà ọ, mo sì bá a ọ wí gẹ́gẹ́ bí ìkà, nítorí tí ẹ̀bi rẹ pọ̀ púpọ̀, ẹ̀ṣẹ̀ rẹ kò sì lóǹkà.
15 Angʼo momiyo iywak kuom adhondi, to in-gi rem ma ok thiedhre? Asekumou kamano nikech richou ngʼeny, kendo nikech timbeu maricho lich.
Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń kígbe nítorí ọgbẹ́ yín, ìrora yín èyí tí kò ní oògùn? Nítorí ọ̀pọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ yín àti ẹ̀bi yín tó ga ni mo fi ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí sí i yín.
16 “‘To jogo duto motiekou notieki; wasiku duto noter e twech. Jogo momayou nomagi; jogo moketonu obadho anaketnegi obadho.
“‘Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ṣe yín ní ibi ni ibi yóò bá, àní gbogbo àwọn ọ̀tá yín ni a ó sọ di àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì; gbogbo àwọn tí wọ́n bà yín jẹ́ ni a ó bàjẹ́.
17 Anamiyi ngima maber kendo anathiedh adhondeni,’ Jehova Nyasaye ema owacho, ‘nikech iluongi ni ngʼama owit oko, Sayun maonge ngʼama dewo.’
Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìlera fún yín, èmi yóò sì wo ọ̀gbẹ́ yín sàn,’ ni Olúwa wí, ‘nítorí tí a pè yín ní alárìnkiri, Sioni tí gbogbo ènìyàn dágunlá sí.’
18 “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: “‘Anaduog mwandu mag hembe Jakobo kendo abed gi ngʼwono e kuondege mag dak; dala maduongʼ noger kendo e kuondege mano okethe, kendo kar dak ruoth noger e kare malongʼo.
“Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Èmi yóò dá gbogbo ìre àgọ́ Jakọbu padà, èmi yóò sì ṣe àánú fún olùgbé àgọ́ rẹ̀; ìlú náà yóò sì di títúnṣe tí ààfin ìlú náà yóò sì wà ní ipò rẹ̀.
19 Jogi nodwok erokamano ka giwer kendo ka gikok gi mor. Anamed kwan mag-gi, kendo ok ginidog chien; mi anamigi duongʼ, kendo ok nokawgi matin.
Láti ẹnu wọn ni orin ọpẹ́ àti ìyìn yóò sì ti máa jáde. Èmi yóò sọ wọ́n di púpọ̀, wọn kì yóò sì dínkù ní iye, Èmi yóò fi ọlá fún wọn, wọn kò sì ní di ẹni àbùkù.
20 Nyithindgi nochal kaka e ndalo machon, kendo anagur anywolagi motegno, mi anakum jogo duto ma thirogi.
Ọmọ ọmọ wọn yóò wà bí i ti ìgbàanì níwájú mi ni wọn yóò sì tẹ àwùjọ wọn dúró sí. Gbogbo ẹni tó bá ni wọ́n lára, ni èmi yóò fì ìyà jẹ.
21 Jatendgi nobed achiel kuomgi; jatendgi noa e diergi. Anakele machiegni kendo enobi machiegni koda, nimar en ngʼa manyalo chiwore, mondo obed machiegni koda?’” Jehova Nyasaye ema owacho.
Ọ̀kan nínú wọn ni yóò jẹ́ olórí wọn, ọba wọn yóò dìde láti àárín wọn. Èmi yóò mú un wá sí ọ̀dọ̀ mi, òun yóò sì súnmọ́ mi, nítorí ta ni ẹni náà tí yóò fi ara rẹ̀ jì láti súnmọ́ mi?’ ni Olúwa wí.
22 “‘Omiyo unubed joga, kendo anabed Nyasachu.’”
‘Nítorí náà, ẹ̀yin yóò jẹ́ ènìyàn mi, èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run yín.’”
23 Neuru, apaka mar Jehova Nyasaye biro mwomore gi mirimbe, yamo mafuto malich ka futo e wiye joma timbegi mono.
Wò ó, ìbínú Olúwa yóò tú jáde, ìjì líle yóò sì sọ̀kalẹ̀ sórí àwọn ènìyàn búburú.
24 Mirima mager mar Jehova Nyasaye ok nodog chien nyaka one ni ochopo dwaro mar chunye. E ndalo ma biro iniwinj tiend wachni.
Ìbínú ńlá Olúwa kò ní dẹ̀yìn lẹ́yìn àwọn ìkà títí yóò fi mú èrò ọkàn rẹ̀ ṣẹ. Ní àìpẹ́ ọjọ́, òye rẹ̀ yóò yé e yín.

< Jeremia 30 >