< Jeremia 27 >
1 E chakruok mar loch Zedekia wuod Josia ruodh Juda, wachni nobiro ne Jeremia koa ir Jehova Nyasaye:
Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìṣèjọba Sedekiah ọmọ Josiah ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wí pé.
2 Ma e gima Jehova Nyasaye nowachona: “Los jok gi tol kod lodi moriw kendo ikete e ngʼuti.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Ṣe àjàgà àti ọ̀pá irin fún ara rẹ, kí o sì fiwé ọrùn rẹ.
3 Eka ior wach ne ruodhi mag Edom, Moab, Amon, Turo kod Sidon kokalo kuom jombetre mosebiro Jerusalem ir Zedekia ruodh Juda.
Kí o rán ọ̀rọ̀ sí ọba ti Edomu, Moabu, Ammoni, Tire àti Sidoni láti ọwọ́ àwọn ikọ̀ tí ó wá sí Jerusalẹmu sọ́dọ̀ Sedekiah ọba Juda.
4 Migi ote mar jotendgi kendo iwachi ni, ‘Ma e gima Jehova Nyasaye Maratego ma, Nyasach Israel, wacho: “Nyisuru jotendu kama:
Kí o sì pàṣẹ fún wọn láti wí fún àwọn olúwa wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí: “Sọ èyí fún àwọn olúwa rẹ.
5 Kuom tekona maduongʼ asechweyo piny gi joge kod le duto manie iye, kendo achiwo gigagi ne ngʼato angʼata mahero.
Pẹ̀lú agbára ńlá mi àti ọwọ́ nínà mi ni Èmi dá ayé, ènìyàn àti ẹranko tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé, mo sì fún ẹni tí ó wu ọkàn mi.
6 Koro anachiw pinjeu ne jatichna Nebukadneza ruodh Babulon; anami kata le mag bungu winje.
Nísinsin yìí, Èmi yóò fa gbogbo orílẹ̀-èdè rẹ fún Nebukadnessari ọba Babeli ìránṣẹ́ mi; Èmi yóò sì mú àwọn ẹranko búburú wọ̀n-ọn-nì jẹ́ tirẹ̀.
7 Ogendini duto notine kod wuode kod nyakware ma wuowi nyaka kinde mar pinye chopi; eka pinje mangʼeny kod ruodhi maroteke nokete obed jatichgi.
Gbogbo orílẹ̀-èdè ni yóò máa sìn ín àti àwọn ọmọdọ́mọ rẹ̀ títí ilẹ̀ rẹ yóò fi dé; ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè àti àwọn ọba ńlá ni yóò tẹríba fún.
8 “‘“Jehova Nyasaye wacho niya: Kapo ni piny kata gwengʼ moro amora ok noti ne Nebukadneza ruodh Babulon kata kulo wiye e bwo jok mare, to anakum pinyno gi ligangla, kech kod masira, nyaka ane ni atieke gi lwete.
“‘“Ṣùgbọ́n tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan kò bá ní sin Nebukadnessari ọba Babeli, tàbí kí ó tẹ orí rẹ̀ ba ní abẹ́ àjàgà rẹ̀, Èmi yóò fi ìyà jẹ orílẹ̀-èdè náà nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, ni Olúwa wí títí Èmi yóò fi run wọ́n nípa ọwọ́ rẹ̀.
9 Omiyo kik uchik itu ne jonabi magu, jokor wach magu, joloknu lek, jo-nyakalondo kata ajuoke magu manyisou ni ok unutine ruodh Babulon.
Nítorí náà, ẹ má ṣe tẹ́tí sílẹ̀ sí àwọn wòlíì yín, àwọn aláfọ̀ṣẹ yín, àwọn tí ń rọ́ àlá fún un yín, àwọn oṣó yín, tàbí àwọn àjẹ́ yín tí wọ́n ń sọ fún un yín pé, ‘Ẹ̀yin kò ní sin ọba Babeli.’
10 Gikoronu miriambo ma biro miyo idarou mabor gi pinyu; anariembu kendo unutho.
Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ fún un yín èyí tí yóò mú u yín jìnnà réré kúrò ní ilẹ̀ yín; kí Èmi kí ó lè lé yín jáde, kí ẹ̀yin ó sì ṣègbé.
11 To ka oganda moro amora enokulre e bwo jok mar ruodh Babulon mi otine, to anami ogandano odongʼ e pinye owuon mondo opure kendo mondo odagi kanyo, Jehova Nyasaye owacho.”’”
Ṣùgbọ́n bí orílẹ̀-èdè kankan bá tẹ orí rẹ̀ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, tí ó sì sìn ín, Èmi yóò jẹ́ kí orílẹ̀-èdè náà wà lórí ilẹ̀ rẹ̀ láti máa ro ó, àti láti máa gbé ibẹ̀ ni Olúwa wí.”’”
12 Ne amiyo Zedekia ruodh Juda wach achielni. Ne awacho niya, “Kul wiyi e bwo jok mar ruodh Babulon; tine kod joge, to ibiro dak.
Èmi sì sọ ọ̀rọ̀ náà fún Sedekiah ọba Juda wí pé: “Tẹ orí rẹ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, sìn ín ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ yóò sì yè.
13 Angʼo madimi in kod jogi tho e dho ligangla, kech kod masira mano ma Jehova Nyasaye osechano timo ni ogendini ma ok bi tiyone ruodh Babulon?
Kí ló dé tí ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ yóò ṣe kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, èyí tí Olúwa fi ń halẹ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí kò bá sin ọba Babeli?
14 Kik uchik itu ne jonabi mawachonu ni, ‘Ok ubi tiyone ruodh Babulon,’ nimar gikoronu miriambo.
Ẹ má ṣe fetísílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì tí ó ń sọ wí pé, ‘Ẹ̀yin kò ní sin ọba Babeli,’ nítorí pé àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín.
15 Jehova Nyasaye wacho ni, ‘Ok aorogi. Gikoro miriambo e nyinga. Emomiyo, anariembu kendo unulal nono, un kaachiel gi jonabi ma koronu.’”
‘Èmi kò rán wọn ni Olúwa wí. Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ní orúkọ mi. Nítorí náà, Èmi yóò lé wọn, wọn yóò sì ṣègbé, ẹ̀yin pẹ̀lú àwọn wòlíì tí ó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín.’”
16 Eka ne awachone jodolo kod jogi duto niya, “Ma e gima Jehova Nyasaye wacho: Kik uchik itu ne jonabi mawacho ni, ‘Machiegnini koro gigo duto moa e od Jehova Nyasaye ibiro duogi koa Babulon.’ Gikoronu miriambo.
Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn àlùfáà àti gbogbo àwọn ènìyàn náà wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ, ẹ má ṣe fetí sí nǹkan tí àwọn wòlíì ń sọ pé, ‘Láìpẹ́ ohun èlò ilé Olúwa ni a ó kó padà láti Babeli,’ àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ. Ẹ má tẹ́tí sí wọn.
17 Kik iwinjgi. Tine ruodh Babulon, to inibed mangima. Angʼo momiyo dala maduongʼni nyaka kethi?
Má ṣe tẹ́tí sí wọn, ẹ máa sin ọba Babeli, ẹ̀yin yóò sì yè. Èéṣe tí ìlú yóò fi di ahoro?
18 Ka gin jonabi kendo gin-gi wach Jehova Nyasaye, to mondo gikwa Jehova Nyasaye Maratego gigo mabeyo modongʼ e od Jehova Nyasaye kod e kar dak mar ruodh Juda kod e Jerusalem kik ter Babulon.
Tí wọ́n bá jẹ́ wòlíì, tí wọ́n sì ní ọ̀rọ̀ Olúwa, jẹ́ kí wọ́n bẹ Olúwa àwọn ọmọ-ogun kí a má ṣe kó ohun èlò tí ó kù ní ilé Olúwa àti ní ààfin ọba Juda àti Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
19 Nimar ma e gima Jehova Nyasaye Maratego wacho kuom sirni, Nam, gik minyalo tingʼ kod gik mamoko modongʼ e dala maduongʼni,
Nítorí pé, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ nípa àwọn opó, omi Òkun ní ti ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti ní ti ohun èlò ìyókù tí ó kù ní ìlú náà.
20 mane Nebukadneza ruodh Babulon ne ok okawo sa mane otero Jehoyakin wuod Jehoyakim ruodh Juda e twech kogole Jerusalem nyaka Babulon kaachiel gi joka ruoth moa Juda gi Jerusalem,
Èyí tí Nebukadnessari ọba Babeli kò kó lọ nígbà tí ó mú Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babeli, pẹ̀lú àwọn ọlọ́lá Juda àti Jerusalẹmu.
21 ee, ma e gima Jehova Nyasaye Maratego, ma Nyasach Israel, wacho kuom gigo mane odongʼ e od Jehova Nyasaye kendo e kar dak mar ruodh Juda kod e Jerusalem:
Lóòótọ́, èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí nípa àwọn ohun ìṣúra tí ó ṣẹ́kù ní ilé Olúwa àti ní ààfin ọba Juda àti ní Jerusalẹmu:
22 ‘Notergi Babulon kendo kanyo ginidongʼ nyaka odiechiengʼ ma anabi kawogie. Eka anadwog-gi kendo aketgi kae.’” Jehova Nyasaye owacho.
‘A ó mú wọn lọ sí ilẹ̀ Babeli, ní ibẹ̀ ni wọn ó sì wà títí di ìgbà tí mo bá padà,’ èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa. ‘Lẹ́yìn èyí, Èmi yóò mú wọn padà, Èmi yóò sì ṣe wọ́n lọ́jọ̀ ní ibí yìí.’”