< Hosea 13 >

1 Kane Efraim owuoyo, to ji ne tetni, nodhiale e piny Israel. To notimo richo kuom lamo Baal, mi notho.
Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì, a gbé e ga ní Israẹli ṣùgbọ́n ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pé ó ń sin òrìṣà Baali, ó sì kú.
2 Koro gimedo timo richo, bende giloso nyisechegi mag fedha mondo gilam, ma gin kido molos gi rieko mangʼeny, magi duto gin tich jopa bepe. Wachore kuom jogi niya, “Gitimo misango gi dhano, kendo ginyodho kido molos mar nyaroya.”
Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀; wọn fi fàdákà ṣe ère òrìṣà fúnra wọn; ère tí a fi ọgbọ́n dá àrà sí, gbogbo wọn jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀nà. Wọn ń sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Pé, “Jẹ́ kí àwọn ènìyàn tí ń rú ẹbọ fi ẹnu, ko àwọn ẹgbọrọ màlúù ni ẹnu.”
3 Emomiyo ginichal mana kaka ongʼwengʼo mokinyi, bende kaka thoo mar okinyi malal nono ka nyango owuok, bende kaka mihudhwe ma yamo keyo kar dino, bende kaka iro mawuok e dirisa.
Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀, bí ìrì òwúrọ̀ kùtùkùtù tó máa ń parẹ́, bí i èèpo ìyẹ̀fun tí afẹ́fẹ́ gbé láti ibi ìpakà bí èéfín tó rú jáde gba ojú fèrèsé.
4 “To An e Jehova Nyasaye ma Nyasachu mane ogolou ua e piny Misri. Ok unyal yango Nyasaye moro amora ma ok An, onge Jawar machielo makmana An.
“Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ẹni tó mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá. Ìwọ̀ kì yóò sì mọ ọlọ́run mìíràn àfi èmi kò sí olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi.
5 Ne aritou e piny motwo, maliel ka mach.
Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù, ní ilẹ̀ tí ó gbẹ tí kò ní omi.
6 Kane apidhogi ne giyiengʼ chuth; kane giseyiengʼ to sunga nomakogi; ma wigi owil koda.
Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ, Nígbà tí wọ́n ní ìtẹ́lọ́rùn tan wọ́n di agbéraga. Nígbà náà ni wọ́n sì gbàgbé mi.
7 Omiyo anabi irgi ka sibuor, kendo ka kwach abiro buto negi e bath yo.
Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún, Èmi yóò fi ara pamọ́ dè wọ́n lọ́nà bí i ẹkùn.
8 Anamonjgi mi ayiechgi matindo tindo mana ka ondiek ma omaa nyithinde. Anatiekgi mana ka sibuor, bende le mag bungu noyiechgi matindo tindo.
Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà, Èmi yóò bá wọn jà bí? Èmi yóò sì fà wọ́n ya bí ìgbà tí ẹkùn bá fa ara wọn ya bi ẹranko búburú ni èmi yóò fa wọn ya.
9 “Osetieku yaye Israel, nikech ok udwara, ok udwar jakonyu.
“A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli, nítorí pé ìwọ lòdì sí mi, ìwọ lòdì sí olùrànlọ́wọ́ rẹ.
10 Ere ruodhu mondo koro oresu? Ere jotendu e miechu, mane usekwayo ni, ‘Miwa ruodh kod jotendwa?’
Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là? Níbo ni àwọn olórí ìlú yín wà, àwọn tí ẹ sọ pé, ‘Fún wa ní ọba àti ọmọ-aládé’?
11 Kuom ich wangʼ mare ne amiyou ruoth kendo e mirimba ne agole oko.
Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba, nínú ìbínú gbígbóná mi, mo sì mú un kúrò.
12 Timbe mamono mag Efraim osekan, kendo richoge osendik e kitabu.
Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wà nínú àkọsílẹ̀.
13 Rem machalo gi mar dhako mamuoch kayo nobine, to en nyathi maonge gi rieko, ma ka sa ochopo monego owuog e ich to okia kama iwuok godo.
Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ tí kò lọ́gbọ́n, nígbà tí àsìkò tó, ó kọ̀ láti jáde síta láti inú.
14 “Abiro resogi kuom teko mar piny joma otho kendo anakonygi kuom tho. In tho, ere masicheni duto, kata in piny joma otho, ere kethruokni? “Ok anakeche, (Sheol h7585)
“Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú. Èmi yóò rà wọ́n padà lọ́wọ́ ikú, ikú, àjàkálẹ̀-ààrùn rẹ dà? Isà òkú, ìparun rẹ dà? “Èmi kò ní ṣàánú mọ́. (Sheol h7585)
15 kata ka obedo ni odhi maber kamano e kind owetene. Yamb yor wuok chiengʼ moa ir Jehova Nyasaye nobi, kakudho koa e piny motwo, ma pigene mag sokni mamol nodwon, kod yewni mokuny bende nodwon. Mwandune manie dechege noyaki duto.
Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀ afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ọ̀dọ̀ Olúwa yóò wá, yóò fẹ́ wá láti inú aginjù orísun omi rẹ̀ yóò gbẹ kànga rẹ̀ yóò gbẹ pẹ̀lú olè yóò fọ́ ilé ẹrù àti gbogbo ilé ìṣúra rẹ̀.
16 Jo-Samaria nokum kuom richogi nikech gisengʼanyo ne Nyasachgi. Noneg-gi gi ligangla; nyithindgi matindo nochwad piny, to mondgi mapek nobar iyegi.”
Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn, nítorí pé wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí Ọlọ́run wọn. Wọn ó ti ipa idà ṣubú; a ó fọ́ àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀, a ó sì la àwọn aboyún wọn nínú.”

< Hosea 13 >