< Hosea 11 >
1 “Ka Israel ne pod nyathi, ne ahere, kendo ne aluongo wuoda ka agolo Misri.
“Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀, mo sì pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.
2 To kaka ne amedo luongo Israel e kaka nomedo dhi mabor koda. Negichiwo misengini ne Baal kendo wangʼo ubani ne kido molosi.
Bí a ti ń pe wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń sá kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn rú ẹbọ sí Baali, wọn sì fi tùràrí jóná sí ère fínfín.
3 An owuon ema napuonjo Efraim wuotho, ka amakogi gi bedegi, to ne ok gifwenyo ni ne en An mane ochangogi.
Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀lú ní ìrìn mo di wọ́n mú ní apá, ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo ti mú wọn láradá.
4 Ne atelonegi gi ngʼwono mathoth kaachiel gihera ma ok rum; ne agolo jok mapek e ngʼutgi kendo akulora piny mondo apidhgi.
Mo fi okùn ènìyàn fà wọ́n àti ìdè ìfẹ́. Mo mú àjàgà kúrò ni ọrùn wọn, Mo sì fi ara balẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.
5 “Donge ginidog Misri kendo Asuria nobedi gi loch kuomgi, nikech gitamore weyo richogi?
“Ṣé wọn ò wá ní padà sí Ejibiti bí. Ṣé Asiria kò sì ní jẹ ọba lé wọn lórí bí nítorí pé wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronúpìwàdà?
6 Ligangla nomil e miechgi madongo manoketh lodi mag rangeyegi, kendo chenro duto magin-go norum.
Idà yóò kọ mọ̀nà ní gbogbo ìlú wọn yóò si bá gbogbo irin ẹnu odi ìlú wọn jẹ́ yóò sì fi òpin sí gbogbo èrò wọn.
7 Joga oramo chuth mondo oweya. Kata giluong Nyasaye Man Malo Moloyo, to ok notingʼ-gi malo e yo moro amora.
Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi bí wọ́n tilẹ̀ pè wọ́n sọ́dọ̀ Ọ̀gá-ògo jùlọ, kò ní gbé wọn ga rárá.
8 “Ere kaka anyalo jwangʼou, Efraim? Ere kaka dabolu Israel? Ere kaka datiu ka Adma? Ere kaka damiu ubed machal gi Zeboim? Ok anyal timonu kamano; nikech aseloko pacha kendo akechou.
“Báwo ni èmi ó ṣe fi ọ́ sílẹ̀, Efraimu? Báwo ni èmi ó ṣe yọ̀ǹda rẹ̀, Israẹli? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Adma? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Seboimu? Ọkàn mi yípadà nínú mi àánú mi sì ru sókè.
9 Ok anaol mirimba mager bende ok analokra mi aketh Efraim bende. Nimar an Nyasaye, ok an dhano, Jal Maler e dieru. Ok anabi gi mirima.
Èmi kò ni mú ìbínú gbígbóná mi ṣẹ, tàbí kí èmi wá sọ Efraimu di ahoro. Nítorí pé èmi ni Ọlọ́run, àní, èmi kì í ṣe ènìyàn. Ẹni mímọ́ láàrín yín, Èmi kò ní í wá nínú ìbínú.
10 Gibiro luwo Jehova Nyasaye, noruti ka sibuor. Kuruto, to nyithinde duto nobi ire katetni kagiwuok yo podho chiengʼ.
Wọn yóò máa tẹ̀lé Olúwa; òun yóò bú ramúramù bí i kìnnìún. Nígbà tó bá bú, àwọn ọmọ rẹ yóò wá ní ìwárìrì láti ìwọ̀-oòrùn.
11 Ginibi ire ka gitetni ka winy moa Misri, ka akuche moa Asuria. Anami gibed e miechgi,” Jehova Nyasaye owacho.
Wọn ó wá pẹ̀lú ẹ̀rù bí i ẹyẹ láti Ejibiti, bí i àdàbà láti Asiria, Èmi ó mú wọn padà sí ilé wọn,” ni Olúwa wí.
12 Efraim oselwora gi miriambo, od jo-Israel en kar wuond. Juda ok winj Nyasaye; adier ok giwinj Jal Maler ma ja-adiera.
Efraimu tí fi irọ́ yí mi ká ilé Israẹli pẹ̀lú ẹ̀tàn. Ṣùgbọ́n Juda sì dúró ṣinṣin pẹ̀lú Ọlọ́run. Ó sì ṣe olóòtítọ́ sí Ẹni mímọ́ Israẹli.