< Chakruok 20 >

1 Ibrahim nowuotho moa kanyo modhi e gwenge mag Negev kendo odak e kind Kadesh kod Shur. Nodak Gerar kuom kinde matin,
Abrahamu sì kó kúrò níbẹ̀ lọ sí ìhà gúúsù ó sì ń gbé ní agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó sì gbé ní ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀.
2 kendo kanyo ema Ibrahim nowachonegi niya, “Sara en nyaminwa.” Eka Abimelek ruodh Gerar nooro joote moomone Sara kendo nokawe kaka chiege.
Abrahamu sì sọ ní ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ pé, “Arábìnrin mi ni.” Abimeleki ọba Gerari sì ránṣẹ́ mú Sara wá sí ààfin rẹ̀.
3 To Nyasaye nofwenyore ne Abimelek e lek gotieno kendo owachone niya, “Dine ber ka itho nikech dhako ma ikawono; en chi ngʼato.”
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki wá ní ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó sì wí fún un pé, “Kíyèsi, kò sí ohun tí o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin tí ìwọ mú sọ́dọ̀ n nì, aya ẹni kan ní íṣe.”
4 To ne oyudo Abimelek pok oriwore kode. Eka nowacho niya, “Jehova Nyasaye bende dineg joma onge ketho?
Ṣùgbọ́n Abimeleki kò tí ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó wí pé, “Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi bí?
5 Donge ne onyisa ni ma nyaminwa; kendo donge Sara ema nowachona ni ma owadwa? Asetimo ma giparo malongʼo kod lwedo maler.”
Ǹjẹ́ òun kò sọ fún mi pé, ‘Arábìnrin mi ni,’ obìnrin náà pẹ̀lú sì sọ pé, ‘Arákùnrin mí ni’? Ní òtítọ́ pẹ̀lú ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí.”
6 Eka Nyasaye nowachone e lek niya, “Ee angʼeyo ni nitimo ma kod paro malongʼo omiyo aseriti mondo kik iketh e nyima. Mano ema nomiyo ok ayieni mondo iriwri kode.
Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún un nínú àlá náà pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé pẹ̀lú òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ọ́ mọ́ tí ń kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ sí mi. Ìdí nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin náà.
7 Koro dwokne Ibrahim chiege, nimar en janabi, kendo obiro lamoni mi ok initho. To ka ok idwoke, to bed gadiera ni in gi jogi duto ubiro tho.”
Nísinsin yìí, dá aya ọkùnrin náà padà, nítorí pé wòlíì ni, yóò sì gbàdúrà fún ọ, ìwọ yóò sì yè. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá dá a padà, mọ̀ dájú pé ìwọ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tìrẹ yóò kú.”
8 Kinyne gokinyi mangʼich Abimelek noluongo jotichne duto kendo kane onyisogi gik moko duto mane osetimore, negibedo maluor ahinya.
Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà tí ó sì sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
9 Eka Abimelek noluongo Ibrahim ire mi openje niya, “Angʼo ma isetimonwani? Ere gima rach ma asetimoni ma omiyo isekelo richo maduongʼni kuoma kod pinyruodha? Isetimona gik moko ma ok onego tim ne ngʼato.”
Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó sì wí fún un pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí ìwọ fi mú ìdálẹ́bi ńlá wá sí orí èmi àti ìjọba mi? Kò yẹ kí ìwọ hu irú ìwà yìí sí mi.”
10 Kendo Abimelek nopenjo Ibrahim niya, “En angʼo miparo momiyo itimo gini?”
Abimeleki sì bi Abrahamu pé, “Kín ló dé tí ìwọ fi ṣe èyí?”
11 Ibrahim nodwoke niya, “Ne awacho e chunya ni, ‘Adier luor mar Nyasaye onge ka, kendo gibiro nega nikech chiega.’
Abrahamu sì dáhùn pé, “Mo ṣe èyí nítorí mo rò nínú ara mi pé, ẹ̀yin tí ẹ wà níhìn-ín, ẹ kò bẹ̀rù Ọlọ́run, pé, ẹ sì le pa mí nítorí aya mi.
12 To bende, kuom adier en nyaminwa, ma nyar wuora, to minewa ema opogore; kendo ne akende obedo chiega.
Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni pé arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni wá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, a kì í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo sì fẹ́ ẹ ní aya.
13 Kendo kane Nyasaye ochika mondo awuog e od wuora mondo awuoth e pinje mamoko, nawachone Sara ni, ‘Mae kaka inyalo nyisa ni ihera: Kamoro amora ma wadhiye wach niya, “An owadu.”’”
Nígbà tí Ọlọ́run sì mú mi rìn kiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Èyí ni ọ̀nà tí ó lè gbà fihàn pé ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi tí a bá dé máa sọ pé, “Arákùnrin rẹ ni mí.”’”
14 Eka Abimelek nokelo rombe gi dhok kod wasumbini mamon kod machwo kendo nomiyogi Ibrahim kendo Abimelek nodwokone Ibrahim Sara chiege.
Nígbà náà ni Abimeleki mú àgùntàn àti màlúù wá, àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó sì kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara aya rẹ̀ padà fún un.
15 Kendo Abimelek nowacho niya, “Pinya duto ni e lweti; dag kamoro amora ma ihero.”
Abimeleki sì tún wí fún un pé, “Gbogbo ilẹ̀ mí nìyí níwájú rẹ, máa gbé ní ibikíbi tí o fẹ́ níbẹ̀.”
16 Nonyiso Sara bende niya, “Asemiyo owadu shekel mar fedha maromo alufu achiel mondo obed ranyisi ne jou duto ni ionge gi ketho; nikech ok isetimo gimoro amora marach.”
Abimeleki sì wí fún Sara pé, “Mo fi ẹgbẹ̀rún owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ níwájú gbogbo ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ àti pé, a dá ọ láre pátápátá.”
17 Eka Ibrahim nolamo Nyasaye, kendo Nyasaye nochango Abimelek, chiege kod jotichne ma nyiri mondo omi ginywol nyithindo kendo,
Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ,
18 nimar noyudo ka Jehova Nyasaye osedino ii mon man e od Abimelek nikech Sara chi Ibrahim.
nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.

< Chakruok 20 >