< Ezekiel 8 >
1 Tarik abich dwe mar auchiel higa mar auchiel, kane abet e oda ka jodongo mag Juda nobet e nyima, teko mar Jehova Nyasaye Manyalo Gik Moko Duto nobiro kuoma.
Ní ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà bí mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀lú àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè bà lé mi níbẹ̀.
2 Ne angʼicho, kendo ne aneno gima kite chalo gi dhano. Chakre kama ne chalo nungone kadhi piny, nechalo mach, kite ne ler kendo rieny ka chuma mopiagi.
Nígbà tí mo wò, mo rí ohun kan tí ó jọ ènìyàn. Láti ibi ìbàdí rẹ lọ sísàlẹ̀ dàbí iná, láti ibi ìbàdí yìí sókè sì mọ́lẹ̀ bí idẹ tó ń kọ mọ̀nà.
3 Norieyo gimoro mane chalo gi bat mine okawa gi yie wiya. Roho mar Nyasaye notingʼa malo nyaka kind piny gi polo, kendo ka an ei fweny mag Nyasaye, notera Jerusalem, nyaka kama idonjogo e rangach man yo nyandwat, mar agola maiye, kama ne nitie kido mar nyasaye manono ma Nyasaye mon-go.
Ó na ohun tó dàbí ọwọ́ jáde, ó fi gba mi ní irun orí mú, Ẹ̀mí sì gbé mi sókè sí agbede-méjì ayé àti ọ̀run, ó sì mú mi lọ rí ìran Ọlọ́run, mo sì lọ sí Jerusalẹmu, ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òde àríwá níbi tí ère owú tí ó ń mú ni bínú wá níwájú mi.
4 Kendo e nyima kanyo, ne nitie duongʼ mar Nyasaye mar Israel, mana kaka nobet e fweny mane aseneno e holocha.
Sì kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli wà níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìran ti mo rí ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.
5 Eka nowachona niya, “Wuod dhano, ngʼi yo nyandwat.” Ne angʼiyo kuno, kendo ei kar donjo man yo nyandwat mar rangach michopogo e kendo mar misango, ne aneno kido mar nyasaye manono ma Nyasaye mon-go.
Ó sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbójú sókè sí ìhà àríwá.” Èmi náà sì gbójú sókè sí ìhà àríwá mo sì rí ère tí ó ń mú ni jowú ní ẹnu-ọ̀nà ibi pẹpẹ.
6 Nowachona kendo niya, “Wuod dhano, bende ineno gik ma dhood Israel timo ka, ma gin gik mamono mokalo awacha, gik mabiro riemba mabor gi kara maler mar lemo? To ibiro medo neno gik moko maricho moloyo mago.”
Ó sì wí fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o rí ohun tí wọ́n ń ṣe ohun ìríra ńlá tí ilé Israẹli ń ṣe, láti lé mi jìnnà réré sí ibi mímọ́ mi? Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tún rí àwọn ìríra ńlá tó tóbi jù èyí lọ.”
7 Eka nokela nyaka kama idonjogo e laru. Ne angʼicho mine aneno bur e kor ot.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà àgbàlá. Mo wò ó, mo sì rí ihò kan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ògiri.
8 Nowachona niya, “Wuod dhano, koro kuny kor ot.” Omiyo ne akunyo kor ot kendo ne aneno dhoot kanyo.
Nígbà náà ló sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbẹ́ inú ògiri náà,” nígbà tí mo sì gbẹ́ inú ògiri, mo rí ìlẹ̀kùn kan.
9 To nowachona niya, “Donji e iye mondo ine gik maricho kendo makwero ma gitimo kanyo.”
Ó sì wí fún mi pé, “Wọlé kí ìwọ kí ó rí ohun ìríra búburú tí wọ́n ń ṣe níbẹ̀.”
10 Omiyo ne adonjo e iye, kendo ne angʼicho, mi aneno kit gik mamol duto kod le makwero kod nyiseche molosi mag dhood Israel, kogor e kor odni.
Mo wọlé, mo sì rí àwòrán oríṣìíríṣìí ẹranko tí ń fà nílẹ̀ àti àwọn ẹranko ìríra àti gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Israẹli tí wọ́n yà sára ògiri.
11 Jodongo piero abiriyo mag dhood Israel nochungʼ e nyimgi, kendo Jazania wuod Shafan nochungʼ kodgi kanyo. Moro ka moro kuomgi notingʼo san miwangʼe ubani e lwete, kendo ubani ne dhwolo iro madungʼ tik kochomo malo.
Níwájú wọn ni àádọ́rin ọkùnrin tó jẹ́ àgbàgbà ilé Israẹli dúró sí, Jaaṣaniah ọmọ Ṣafani sì dúró sí àárín wọn. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì mú àwo tùràrí lọ́wọ́, òórùn sì ń tú jáde.
12 Nowachona niya, “Wuod dhano, bende iseneno gik ma jodong dhood Israel timo e mudho, ka ngʼato ka ngʼato kuomgi odich mana e abich nyasache? Giwacho ni, ‘Jehova Nyasaye ok newa; nikech Jehova Nyasaye osejwangʼo piny.’”
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o ti rí ohun tí àwọn àgbàgbà ilé Israẹli ń ṣe nínú òkùnkùn, olúkúlùkù ní yàrá òrìṣà rẹ̀? Wọ́n ní, ‘Olúwa kò rí wa; Olúwa ti kọ̀ ilé náà sílẹ̀.’”
13 Nochako owacho kendo niya, “Ibiro nenogi ka gitimo gik mochido moloyo misenenogo.”
Ó tún sọ fún mi pé, “Ìwọ yóò rí wọn tí wọ́n ń ṣe àwọn ohun ìríra tó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ.”
14 Eka nokela nyaka kama idonjogo e dhorangach man yo nyandwat mar od Jehova Nyasaye, kendo naneno mon kobet kanyo, ka ywago Tamuz.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sì ń ṣọ̀fọ̀ fún Tamusi.
15 Nowachona ni, “Bende ineno gima timoreni, wuod dhano? Ibiro neno gik mochido moloyo ma.”
Ó sọ fún mi pé, “Ṣé ìwọ rí báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún rí ìríra tó ga jù èyí lọ.”
16 Eka nokela e laru maiye mar od Jehova Nyasaye, kendo kanyo, gie kama idonjogo e hekalu, e kind kendo mar misango gi kama owe yo mikadhe, ne nitie ji madirom piero ariyo gabich. Negiloko dier ngʼegi ni hekalu mar Jehova Nyasaye, kendo ka wengegi ochomo yo wuok chiengʼ, negikulore ne wangʼ chiengʼ man yo wuok chiengʼ.
Ó mú mi wá sí ibi àgbàlá ilé Olúwa, ní ẹnu-ọ̀nà tẹmpili Olúwa, láàrín ìloro àti pẹpẹ, ni ìwọ̀n ọkùnrin mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n wà, tí wọ́n kẹ́yìn sí tẹmpili Olúwa tí wọn sì kọjú sí ìlà-oòrùn, wọ́n sì ń foríbalẹ̀ fún oòrùn ní apá ìlà-oòrùn.
17 Nopenja niya, “Bende ineno gima timoreni, wuod dhano? Bende en wach matin adier mondo jo-Juda odhi nyime gi gik mamono ma gitimo kaeni? Bende owinjore gipongʼ piny gi mahundu kendo gidhi nyime giwangʼo iya? Ne kaka gitwenyona umgi!
Ó sì wí fún mi, “Ṣé ìwọ ti rí èyí ọmọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ohun kékeré ni fún ilé Juda láti ṣe àwọn ohun ìríra tí wọn ń ṣe níbi yìí? Ṣé o tún yẹ kí wọ́n fi ìwà ipá kún ilẹ̀ kí wọn sì máa mú mi bínú ní gbogbo ìgbà? Wò wọn bi wọn ṣe n fi ẹ̀ka wọn sínú inú wọn.
18 Emomiyo koro abiro tiyo kodgi gi mirima. Ok abi timonegi tim ngʼwono kendo ok abi weyo mak akumogi. Kata obedo ni gilama matek manade, to ok anadewgi ngangʼ!”
Nítorí náà, èmi yóò fi ìbínú bá wọn wí; èmi kò ní i dá wọn sí bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì ní fojú àánú wò wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ ń pariwo sí mi létí, èmi kò ní fetí sí wọn.”