< 2 Samuel 1 >

1 Bangʼ kane Saulo osetho, Daudi noduogo koa e lweny mane oloyoe jo-Amalek mi nonindo Ziklag ndalo ariyo.
Lẹ́yìn ikú Saulu, Dafidi ti ibi tí ó ti ṣẹ́gun àwọn ará Amaleki bọ̀, ó sì dúró ní Siklagi ní ọjọ́ méjì.
2 Chiengʼ mar adek ngʼato nobiro koa e kambi mar Saulo korwako lewni moyiech to wiye otimo buru, kane ochopo ir Daudi nokulore nyaka piny komiye duongʼ.
Ní ọjọ́ kẹta, ọkùnrin kan dé láti ibi ibùdó Saulu, pẹ̀lú aṣọ rẹ̀ tí ó ti ya; àti erùpẹ̀ ní orí rẹ̀. Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Dafidi, ó wólẹ̀ fún un láti bu ọlá fún un.
3 Daudi nopenje niya, “Ia kanye?” Nodwoke niya, “Atony kawuok e kambi mar jo-Israel.”
Dafidi sì béèrè pé, “Ibo ni ìwọ ti wá?” “Èmi sá láti ibùdó àwọn ọmọ Israẹli.”
4 Daudi nopenjo niya, “Wachnane, angʼo manotimore?” Nodwoke niya, “Ji noringo kawuok e lweny. Ngʼenygi nonegi kendo Saulo gi Jonathan wuode bende otho.”
Dafidi béèrè pé, “Kí ni ó ṣẹlẹ̀?” “Sọ fún mi.” Ó wí pé, “Àwọn ọkùnrin náà sá láti ojú ogun. Ọ̀pọ̀ wọn ṣubú, wọ́n sì kú. Saulu àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin Jonatani sì kú pẹ̀lú.”
5 Eka Daudi nowachone wuowi mane okelone wach niya, “Ere kaka ingʼeyo ni Saulo gi wuode Jonathan osetho?”
Nígbà náà, ní Dafidi sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó mú ìròyìn wá fún un pé, “Báwo ni o ṣe mọ̀ pé Saulu àti ọmọkùnrin rẹ̀ Jonatani ti kú.”
6 Wuowino nodwoke niya, “Ne oyudo ka an e got Gilboa kendo ne aneno Saulo kochwowore gi tongʼe, ka geche lweny kod joidhgi mane lawe ne chiegni juke.”
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà sọ pé, “Mo wà ní orí òkè Gilboa níbẹ̀ ni Saulu fi ara tí ọkọ̀ rẹ̀, àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin sì ń lépa rẹ̀.
7 Kane olokore monena, noluonga, mine apenje ni, Angʼo midwaro mondo atim?
Nígbà tí ó wò yíká, tí ó rí mí, ó pè mi, mo sì wí pé, ‘Kí ni mo lè ṣe?’
8 “Nopenja ni, ‘In ngʼa?’ “Ne adwoke ni, ‘An ja-Amalek.’
“Ó bi mí wí pé, ‘Ta ni ìwọ?’ “Mo dáhùn pé, ‘Ará a Amaleki.’
9 “Eka nowachona ni, ‘Sud ira ka mondo inega! Nikech awinjo rem malit to ngimana pod nitie.’
“Nígbà náà ó wí fún mi pé, ‘Dúró lórí ì mi kí o sì pa mí! Èmi wà nínú ìrora ikú, ṣùgbọ́n mo wà láààyè.’
10 “Omiyo ne asudo bute mi anege, nikech ne angʼeyo ni kaka ne osepodho ne ok onyal chungʼ malo mi otony. Ne akawo osimbo mar loch mane ni e wiye gi bangli mane ni e kor bade kendo asekelogi ka ni ruodha.”
“Nígbà náà, mo dúró lórí i rẹ̀, mo sì pa á nítorí mo mọ̀ wí pé, lẹ́yìn ìgbà tí ó ti ṣubú, kò le è yè mọ́. Mo sì mú adé tí ó wà lórí rẹ̀, idẹ tí ó wà ní apá a rẹ̀, mo sì kó wọn wá síbí fún olúwa mi.”
11 Eka Daudi gi joma nenikode nomako lepgi moyiecho.
Nígbà náà ni, Dafidi àti gbogbo àwọn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, di aṣọ wọn mú, wọ́n sì fà á ya.
12 Negikuyo ka giywak kendo ka giriyo kech nyaka ochopo odhiambo, ka giywago Saulo gi wuode Jonathan, to gi jolweny mag Jehova Nyasaye to gi jo-Israel, nikech ne oseneg-gi gi ligangla.
Wọ́n ṣọ̀fọ̀, wọ́n sì sọkún, wọ́n sì gbààwẹ̀ títí di ìrọ̀lẹ́ fún Saulu àti ọmọ rẹ̀ Jonatani àti fún àwọn ọmọ-ogun Olúwa, àti fún àwọn ilé Israẹli, nítorí wọ́n ti ṣubú nípa idà.
13 Daudi nowacho ni rawera mane okelone wach niya, “In jakanye?” Nodwoke niya, “An wuod jadak ma ja-Amalek.”
Dafidi sọ fún ọkùnrin tí ó mú ìròyìn wá fún un pé, “Níbo ni ó ti wá?” O dáhùn pé, “Ọmọ àlejò ni mo jẹ́, ará Amaleki.”
14 Daudi nopenje niya, “Angʼo momiyo ne ok iluor mar tingʼo badi kinego ngʼat Jehova Nyasaye mowir?”
Dafidi béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni ó dé tí ìwọ kò fi bẹ̀rù láti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè láti fi pa ẹni àmì òróró Olúwa?”
15 Eka Daudi noluongo achiel kuom joge mowachone niya, “Dhi inege!” Omiyo ngʼatno nochwowe motho.
Nígbà náà Dafidi pe ọ̀kan nínú ọkùnrin, ó sì wí pé, “Lọ, gbé e lulẹ̀!” Nígbà náà ó gbé e lulẹ̀, ó sì kú.
16 Nimar Daudi nosewachone niya, “Rembi obedi e wiyi iwuon. Dhogi ema osebedo janeno mari ka iwacho ni, ‘Asenego ngʼat Jehova Nyasaye mowir.’”
Nítorí Dafidi wí fún un pé, “Ẹ̀jẹ̀ rẹ yóò wà lórí ara rẹ, nítorí ẹnu ara rẹ ni o fi sọ pé, ‘Mo pa ẹni àmì òróró Olúwa.’”
17 Daudi nochwogo wend ywak miywagogo Saulo gi wuode Jonathan,
Dafidi sì fi orin ọ̀fọ̀ yìí ṣọ̀fọ̀ lórí Saulu àti lórí Jonatani ọmọ rẹ̀,
18 kendo nochiko mondo opuonj jo-Juda wend ywak mar atungʼ mondiki e Kitabu mar Jasher kama:
Ó sì pàṣẹ pé kí a kọ́ àwọn ọkùnrin Juda ní orin arò yìí tí ó jẹ́ ti ọrun (a kọ ọ́ sí inú ìwé Jaṣari):
19 “Yaye Israel, jogi moluor oriere piny konegi e gode maboyo. Mano kaka roteke osepodho.
“Ògo rẹ, Israẹli ni a pa ní òkè gíga rẹ. Wò bí àwọn alágbára ṣe ń ṣubú!
20 “Kik iwach wachni e piny Gath, kik ihul wachni e yore man Ashkelon, nono to dimi nyi jo-Filistia bed moil, bende dimi nyi joma ok oter nyangu bed moil.
“Ẹ má ṣe sọ ọ́ ní Gati, ẹ má ṣe kéde rẹ̀ ní òpópónà Aṣkeloni, kí àwọn ọmọbìnrin Filistini má bá à yọ̀, kí àwọn ọmọbìnrin aláìkọlà má ba à dunnú.
21 “Yaye gode mag Gilboa, mad ibed maonge thoo kata koth, kata puothe machiego cham michiwo. Nimar kanyo ema ne odwanye kuodi mag joma rateke, kuodi mag Saulo, tinde ok wir gi mo.
“Ẹ̀yin òkè Gilboa, kí ẹ̀yin kí ó má ṣe rí ìrì tàbí òjò, tàbí oko tí ó mú èso ọrẹ wá. Nítorí ibẹ̀ ni asà alágbára ti ṣègbé, asà Saulu, bí ẹni pé a kò fi òróró yàn án.
22 Koa kuom remb joma nonegi, koa kuom ringre joma rateke, atungʼ mar Jonathan ne ok odwogo, ligangla mar Saulo ne ok odwogo nono.
“Ọrun Jonatani kì í padà bẹ́ẹ̀ ni idà Saulu kì í padà lásán, láì kan ẹ̀jẹ̀ àwọn tí a pa, àti ẹran àwọn alágbára.
23 “Saulo gi Jonathan ne oher kendo ne gin joma longʼo kane gingima, kendo e kinde thogi ne ok gipogore. Negiringo matek maloyo ongo, kendo ne gitek maloyo sibuor.
Saulu àti Jonatani— ní ọjọ́ ayé, wọ́n fẹ́ràn ara, wọn sì dùn, ní ikú, wọn kò sì yà ara wọ́n. Wọ́n yára ju idì lọ, wọ́n lágbára ju kìnnìún lọ.
24 “Yaye nyi Israel, ywaguru Saulo, mane orwakou gi lewni makwar kendo marep-rep, mane oduso lepu gi gik molos gi dhahabu.
“Ẹ̀yin ọmọbìnrin Israẹli, ẹ sọkún lórí Saulu, ẹni tí ó fi aṣọ ọ̀gbọ̀ dáradára wọ̀ yín, ẹni tí ó fi wúrà sí ara aṣọ yín.
25 “Mano kaka joma rateke osetho e lweny! Jonathan onindo konegi e godeu maboyo.
“Wò ó bí alágbára ti ṣubú ní ojú ogun! Jonatani, ìwọ tí a pa ní òkè gíga.
26 Aywagi malit, Jonathan omera; ne ageni ahinya. Herani koda ne lich miwuoro, moloyo hera mar mon.
Ọkàn mi gbọgbẹ́ fún ọ Jonatani arákùnrin mi; ìwọ ṣọ̀wọ́n fún mi. Ìfẹ́ rẹ sí mi jẹ́ ìyanu, ó jẹ́ ìyanu ju ti obìnrin lọ.
27 “Mano kaka joma rateke osetho! Kendo gigegi mag lweny osetieki!”
“Wò ó bí alágbára ti ṣubú! Ohun ìjà sì ti ṣègbé!”

< 2 Samuel 1 >