< 2 Weche Mag Ndalo 18 >

1 Jehoshafat koro ne nigi mwandu mangʼeny kod huma malach, bende notimo winjruok gi Ahab kuom kend.
Nísinsin yìí Jehoṣafati sì ní ọrọ̀ àti ọlá púpọ̀, ó sì dá àna pẹ̀lú Ahabu nípa fífẹ́ ọmọ rẹ̀.
2 Bangʼ higni moko nodhi Samaria limo Ahab. Ahab noyangʼone kaachiel gi joma ne ni kode rombe mangʼeny kod dhok, kendo nokwaye ni mondo oked gi jo-Ramoth Gilead.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, ó sọ̀kalẹ̀ láti lọ bá Ahabu lálejò ní Samaria. Ahabu sì pa àgùntàn àti màlúù púpọ̀ fún àti àwọn ènìyàn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ ó sì rọ̀ ọ́ láti dojú ìjà kọ Ramoti Gileadi.
3 Ahab ruodh jo-Israel nopenjo Jehoshafat ruodh Juda niya, “Ibiro dhi konya kedo gi jo-Ramoth Gilead?” Jehoshafat nodwoke niya, “Wan joka ngʼato achiel, kendo joga gin jogi, wabiro konyi kedo.”
Ahabu ọba Israẹli sì béèrè lọ́wọ́ ọba Jehoṣafati, ọba Juda pé, “Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀lú mi sí Ramoti Gileadi?” Jehoṣafati sì dá a lóhùn pé, “Èmi wà gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe wà, àti àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bí ènìyàn rẹ àwa yóò pẹ̀lú rẹ nínú ogun náà”.
4 To Jehoshafat bende nowachone ruodh Israel niya, “Mokwongo penj ane Jehova Nyasaye wachni.”
Ṣùgbọ́n Jehoṣafati náà sì tún wí fún ọba Israẹli pé, “Kọ́kọ́ béèrè lọ́wọ́ Olúwa.”
5 Omiyo ruodh Israel nochoko jonabi kanyakla maromo ji mia angʼwen mopenjogi niya, “Bende wanyalo dhi kedo gi jo-Ramoth Gilead koso kik adhi?” Negidwoke niya, “Dhiuru nikech Nyasaye nochiwe e lwet ruoth.”
Bẹ́ẹ̀ ọba Israẹli kó àwọn wòlíì papọ̀, irinwó ọkùnrin ó sì bi wọ́n pé, “Kí àwa kí lọ sí ogun Ramoti Gileadi tàbí kí èmi kí ó jọ̀wọ́ rẹ?” Wọ́n dáhùn pé, “Lọ, nítorí tí Ọlọ́run yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
6 To Jehoshafat nopenjo niya, “Donge nitie janabi mar Jehova Nyasaye ka ma dwapenj wach?”
Ṣùgbọ́n Jehoṣafati béèrè pé, “Ṣé kò ha sí wòlíì Olúwa níbí ẹni tí àwa ìbá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?”
7 Ruodh Israel nodwoko Jehoshafat niya, “Pod nitie ngʼato achiel manyalo penjonwa Jehova Nyasaye wach, to ok adware nikech ok okor gimoro amora maber kuoma, to kinde duto mana gik maricho. Nyinge en Mikaya wuod Imla.” Jehoshafat nodwoko niya, “Ruoth, ok onego iwach kamano.”
Ọba Israẹli dá Jehoṣafati lóhùn pé, “Ọkùnrin kan wà síbẹ̀ lọ́dọ̀ ẹni tí àwa ìbá tún béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ṣùgbọ́n èmi kórìíra rẹ̀ nítorí kò jẹ́ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun rere kan nípa mi ṣùgbọ́n bí kò ṣe ohun búburú, ní gbogbo ìgbà òun náà ni Mikaiah ọmọ Imla.” Jehoṣafati sì dá lóhùn pé, “Ọba kò gbọdọ̀ sọ bẹ́ẹ̀.”
8 Omiyo ruodh Israel noluongo achiel kuom jodonge mowachone niya, “Dhi piyo iom Mikaya wuod Imla.”
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli pe ọ̀kan lára àwọn ìjòyè ó sì wí pé, “Ẹ mú Mikaiah ọmọ Imla kí ó yára wá.”
9 Ruodh Israel kod Jehoshafat ruodh Juda noyudo orwako lepgi mag ruoth ka moro ka moro kuomgi obet e kom duongʼne e kar dino cham mantie e dhoranga Samaria, kendo ne gin kod jonabi duto mane koro e nyimgi.
Wọ́n wọ aṣọ ìgúnwà wọn, ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda wọ́n jókòó sórí ìtẹ́ wọ́n ní ìta ẹnu-bodè Samaria, pẹ̀lú gbogbo àwọn wòlíì tí ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn.
10 Koro Zedekia wuod Kenana noloso tunge mag nyinyo kolando niya, “Ma e gima Jehova Nyasaye owacho, ‘Gi chumbegi ibiro chwowo jo-Aram nyaka itiekgi chuth.’”
Nísinsin yìí Sedekiah ọmọ Kenaana sì ti ṣe ìwo irin, ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ: ‘Pẹ̀lú èyí ìwọ yóò kan àwọn ará Siria títí ìwọ ó fi pa wọ́n run.’”
11 Jonabi mamoko duto bende ne koro wach mana machal kamano. Negiwacho niya, “Monj jo-Ramoth Gilead kendo ilogi, nikech Jehova Nyasaye enokete e lwet ruoth.”
Gbogbo àwọn wòlíì tí ó kù ni wọn ń sọtẹ́lẹ̀ ní àkókò kan náà. Wọ́n sì wí pé, “Dojúkọ Ramoti Gileadi ìwọ yóò sì ṣẹ́gun, nítorí Olúwa yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
12 Jaote mane odhi luongo Mikaya nowachone niya, “Jonabi duto osekoro wach achiel machalre, kagiwacho ni gima ber biro timore ni ruoth. In bende yie ikor wach maber kaka gisekorono.”
Ìránṣẹ́ tí ó ti lọ pe Mikaiah sì wí fún un pé, “Ẹ wò ó, gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin kan àti òmíràn wòlíì fi ẹnu kan sọ rere fún ọba. Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ kí ó dàbí ọ̀kan nínú tiwọn, kí o sì sọ rere.”
13 To Mikaya nowacho niya, “Akwongʼora gi nying Jehova Nyasaye mangima ni, anyalo mana nyise gima Nyasacha owacho.”
Ṣùgbọ́n Mikaiah wí pe, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti dájú pé Olúwa ń bẹ láààyè, èmi yóò sọ ohun tí Ọlọ́run mi sọ.”
14 Kane Mikaya ochopo, ruoth nopenje niya, “Bende wanyalo dhi mondo waked gi jo-Ramoth Gilead, koso kik wadhi?” Nodwoke niya, “Ked kodgi kendo iyud loch nimar ibiro chiwgi e lweti.”
Nígbà tí ó dé, ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, “Mikaiah, ṣe kí àwa ki ó lọ sí ogun ti Ramoti Gileadi, tàbí kí àwa kí ó fàsẹ́yìn?” Ó sì dáhùn pé, “Ẹ dojúkọ wọ́n kí ẹ sì ṣẹ́gun, nítorí a ó fi wọ́n lé yín lọ́wọ́.”
15 Ruoth nowachone niya, “Nyaka karangʼo ma anaketi mondo ikwongʼrina gi nying Jehova Nyasaye ni iwacho adiera ma ok miriambo?”
Ọba sì wí fún un pé, “Ìgbà mélòó ni èmi ó fi ọ́ búra láti sọ ohun kan fún mi bí kò ṣe ọ̀rọ̀ òtítọ́ ní orúkọ Olúwa?”
16 Eka Mikaya nodwoke niya, “Ne aneno jo-Israel duto koke ewi gode mana kaka rombe maonge jakwath, kendo Jehova Nyasaye nowacho ni, ‘Jogi onge gi ruoth. Yie iwe ngʼato ka ngʼato odhi e dalane gi kwe.’”
Mikaiah sì dáhùn pé, “Mo rí gbogbo Israẹli túká kiri lórí àwọn òkè bí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́, Olúwa sì wí pé, ‘Àwọn wọ̀nyí kò ní olúwa. Jẹ́ kí olúkúlùkù padà sí ilé rẹ̀ ní àlàáfíà.’”
17 Ruodh Israel nowachone Jehoshafat niya, “Donge nawachoni ni ok okorna gik mabeyo, to okoro mana gik maricho?”
Ọba Israẹli wí fún Jehoṣafati pé, “Ṣe èmi kò sọ fún ọ wí pé òun kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere kankan nípa mi rí, ṣùgbọ́n búburú nìkan?”
18 Mikaya nodhi nyime kawacho niya, “Kuom mano winj wach Jehova Nyasaye: Naneno Jehova Nyasaye kobet e kom duongʼne gi jopolo duto ochungo e bathe korachwich gi koracham.
Mikaiah tẹ̀síwájú pé, “Nítorí náà, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, mo rí Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ gbogbo ogun ọ̀run sì dúró lápá ọ̀tún àti lápá òsì.
19 Kendo Jehova Nyasaye nowacho ni, ‘En ngʼa mabiro hoyo Ahab ruodh Israel mondo oked gi jo-Ramoth Gilead kendo onege kuno?’ “To ngʼato ka ngʼato nochiwo pache.
Olúwa sì wí pé, ‘Ta ni yóò tan Ahabu ọba Israẹli lọ sí Ramoti Gileadi kí ó sì lọ kú ikú rẹ̀ níbẹ̀?’ “Èkínní sì sọ tìhín, òmíràn sì sọ tọ̀hún.
20 Mogik, roho marach nobiro mochungʼ e nyim Jehova Nyasaye mowacho ni, ‘Abiro hoye.’” Jehova Nyasaye nopenje niya, “Ere kaka ibiro hoye?”
Ní ìparí, ni ẹ̀mí kan wá síwájú, ó dúró níwájú Olúwa ó sì wí pé, ‘Èmi yóò tàn án.’ “‘Nípa ọ̀nà wo?’ Olúwa béèrè.
21 Nodwoko niya, “‘Abiro dhi mondo abed roho mar miriambo e dho jonabi mage duto.’” Jehova Nyasaye nodwoke niya, “‘Dhiyo kendo itim kamano nikech in ema ibiro hoye mi iloye.’
“‘Èmi yóò lọ láti lọ di ẹ̀mí èké ní ẹnu gbogbo àwọn wòlíì.’ “‘Ìwọ yóò sì borí nínú ìtànjẹ rẹ̀ báyìí,’ ni Olúwa wí. ‘Lọ kí ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.’
22 “Omiyo koro sani Jehova Nyasaye oseketo roho mar miriambo e dho jonabigi. Jehova Nyasaye osengʼadoni buch masira.”
“Bẹ́ẹ̀ ni nísinsin yìí Olúwa ti fi ẹ̀mí èké sí ẹnu àwọn wòlíì rẹ. Olúwa sì ti sọ ibi sí ọ.”
23 Eka Zedekia wuod Kenana noa malo mopamo lemb Mikaya. Nopenje niya, “En yo mane ma Roho mar Jehova Nyasaye noluwo kobiro wuoyo kodi?”
Nígbà náà Sedekiah ọmọ Kenaana lọ sókè ó sì gbá Mikaiah ní ojú. Ó sì béèrè pé, “Ní ọ̀nà wo ni ẹ̀mí Olúwa gbà kọjá lọ kúrò lọ́dọ̀ mi láti bá ọ sọ̀rọ̀?”
24 Mikaya nodwoke niya, “Ibiro fwenyo chiengʼ ma iniring kidhi pondo e ot maiye.”
Mikaiah sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò ṣe ìwádìí ní ọjọ́ tí ìwọ yóò sá pamọ́ sínú ìyẹ̀wù.”
25 Ruodh Israel nogolo chik niya, “Kawuru Mikaya kendo utere ir Amon jatend dala maduongʼ kendo ir Joash wuod ruoth,
Ọba Israẹli pa á láṣẹ pé, “Mú Mikaiah kí o sì ran padà sí Amoni olórí ìlú àti sí Joaṣi ọmọ ọba,
26 kendo uwachne ni, ‘Gima ruoth wacho ema: Ket ngʼatni e od twech kendo kik imiye gimoro amora makmana makati kod pi nyaka aduogi kangima.’”
Ó sì wí pé, ‘Èyí ni ohun tí ọba sọ, ẹ fi ènìyàn yìí sínú túbú kí ẹ má sì ṣe fún un ní ohunkóhun ṣùgbọ́n àkàrà àti omi títí tí èmi yóò fi dé ní àlàáfíà.’”
27 Mikaya nowachone niya, “Kidwogo kingima, to kara ok asewuoyo gi dho Jehova Nyasaye.” Bangʼe nomedo wacho niya, “Winjuru wechena un ji duto!”
Mikaiah sì wí pe, “Tí ìwọ bá padà ní àlàáfíà, Olúwa kò sọ̀rọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.” Nígbà náà, ó sì fi kún un pé, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn!”
28 Omiyo ruodh Israel gi Jehoshafat ruodh Juda nodhi Ramoth Gilead.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda lọ sókè ní Ramoti Gileadi.
29 Ruodh Israel nowachone Jehoshafat niya, “Abiro rwako lewni moko ka wadhi e lweny mondo kik gifwenya, in to rwak arwaka lepi mag ruoth.” Omiyo ruodh Israel norwako lewni ma ok nyal fwenyego kendo nodhi e lweny.
Ọba Israẹli sọ fún Jehoṣafati pé, “Èmi yóò lọ sí ojú ìjà, ṣùgbọ́n ìwọ wọ aṣọ ìgúnwà rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli pa aṣọ rẹ̀ dà, ó sì lọ sí ojú ìjà.
30 Ruodh jo-Aram nogolo chik ne jotende mariembo geche niya, “Kik uked gi ngʼato angʼata bed ni otin kata oduongʼ makmana ruodh Israel.”
Nísinsin yìí ọba Siria ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ tí ó wà ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ má ṣe jà pẹ̀lú ẹnìkankan, èwe tàbí àgbà àyàfi ọba Israẹli.”
31 Kane jotelo mariembo geche lweny noneno Jehoshafat negiwacho e chunygi niya, “Nyaka bed ni ma e ruodh Israel.” Omiyo negilokore mondo giked kode, to kane Jehoshafat oywak, Jehova Nyasaye nokonye. Nyasaye nogologi kuome,
Nígbà tí àwọn olórí kẹ̀kẹ́ rí Jehoṣafati, wọ́n rò wí pé, “Èyí ní ọba Israẹli.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì yípadà láti bá a jà. Ṣùgbọ́n Jehoṣafati kégbe sókè, Olúwa sì ràn án lọ́wọ́. Ọlọ́run sì lé wọn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀,
32 nikech kane jotelo mariembo geche lweny noneno ni ok en ruodh Israel, negiweyo lawe.
Ó sì ṣe, nígbà tí olórí kẹ̀kẹ́ rí i wí pé kì í ṣe ọba Israẹli, wọ́n sì dáwọ́ lílé rẹ̀ dúró.
33 To ngʼat moro noywayo atungʼ mare modiro asere ma nochwowo ruodh Israel e kind law lweny mane orwako. Ruoth nonyiso jariemb gari niya, “Lok garini mondo igola ka, nimar ahinyora marach.”
Ṣùgbọ́n ẹnìkan fa ọrun rẹ̀ láì pète, ó sì bá ọba Israẹli láàrín ìpàdé ẹ̀wù irin, ọba sì sọ fún olùtọ́jú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ pé, “Yí ọwọ́ rẹ padà, kí o sì wà mí jáde kúrò lójú ìjà. Nítorí èmi ti gbọgbẹ́.”
34 Odiechiengʼno duto lweny nomedo bedo mager kendo noten ruodh Israel e gache komanyore gi jo-Aram nyaka godhiambo mondo ojiw joge. Notho ka chiengʼ dhi podho.
Ní ọjọ́ pípẹ́, ìjà náà sì ń pọ̀ sí i, ọba Israẹli dúró nínú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ kọjú sí àwọn ará Siria títí ó fi di àṣálẹ́. Lẹ́yìn náà ní àkókò ìwọ oòrùn, ó sì kú.

< 2 Weche Mag Ndalo 18 >