< Galatským 1 >
1 Bratři, přijměte ode mne i od všech, kteří jsou zde se mnou, přání Božího pokoje a milosti.
Paulu, aposteli tí a rán kì í ṣe láti ọ̀dọ̀ ènìyàn wá, tàbí nípa ènìyàn, ṣùgbọ́n nípa Jesu Kristi àti Ọlọ́run Baba, ẹni tí ó jí i dìde kúrò nínú òkú.
Àti gbogbo àwọn arákùnrin tí ó wà pẹ̀lú mi, Sí àwọn ìjọ ní Galatia:
Oore-ọ̀fẹ́ sí yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wá àti Jesu Kristi Olúwa,
4 Věčná chvála buď Bohu i Kristu Ježíši, (aiōn )
ẹni tí ó fi òun tìkára rẹ̀ dípò ẹ̀ṣẹ̀ wa, kí ó lè gbà wá kúrò nínú ayé búburú ìsinsin yìí, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọ́run àti Baba wa, (aiōn )
5 který podle Boží vůle za nás obětoval svůj život a tak nás zachránil z moci zla, které ovládá tento svět. (aiōn )
ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín. (aiōn )
6 Jsem překvapen, bratři, jak rychle jste se nechali svést k následování falešného evangelia.
Ó yà mi lẹ́nu pé ẹ tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, sí ìyìnrere mìíràn.
7 Pamatujte si, že není jiná cesta k věčnému životu než ta, kterou nám otevřel Kristus. Nedejte se mýlit těmi, kdo se snaží jeho učení – jak jsme vám ho kázali – všelijak překrucovat. Kdo to činí, ať je na věky zavržen.
Nítòótọ́, kò sí ìyìnrere mìíràn bí ó tilẹ̀ ṣe pé àwọn kan wà, tí ń yọ yín lẹ́nu, tí wọ́n sì ń fẹ́ yí ìyìnrere Kristi padà.
8 Znovu opakuji: I kdyby někdo z nás – nebo dokonce anděl z nebe – hlásal něco jiného, než jsme vás učili my, ať je na věky zavržen.
Ṣùgbọ́n bí ó ṣe àwa ni tàbí angẹli kan láti ọ̀run wá, ni ó bá wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí tí a tí wàásù rẹ̀ fún yín lọ, jẹ́ kí ó di ẹni ìfibú títí láéláé!
Bí àwa ti wí ṣáájú, bẹ́ẹ̀ ni mo sì tún wí nísinsin yìí pé, bí ẹnìkan bá wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí tí ẹ̀yin tí gbà lọ, jẹ́ kí ó di ẹni ìfibú títí láéláé!
10 Vidíte, že nezačínám žádnými lichotkami. Nechci se totiž za každou cenu líbit lidem. Jestliže se chci opravdu někomu líbit, pak jedině Bohu; jinak bych nebyl Kristův služebník.
Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ènìyàn ni èmi ń wá ojúrere rẹ̀ ní tàbí Ọlọ́run? Tàbí ènìyàn ni èmi ń fẹ́ láti wù bí? Bí èmi bá ń fẹ́ láti wu ènìyàn, èmi kò lè jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi.
11 Ujišťuji vás, bratři, že to, co jsem vám hlásal, není lidský výmysl.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀, ará, pé ìyìnrere tí mo tí wàásù kì í ṣe láti ipa ènìyàn.
12 To poselství mi nesvěřil nikdo jiný než sám Ježíš Kristus. Jsou to jeho vlastní slova a nemám je z druhé ruky.
N kò gbà á lọ́wọ́ ènìyàn kankan, bẹ́ẹ̀ ni a kò fi kọ́ mi, ṣùgbọ́n mo gbà á nípa ìfihàn láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi.
13 Vy přece víte, čeho jsem se dopouštěl ještě jako žid – jak jsem křesťany pronásledoval a snažil se je vyhubit.
Nítorí ẹ̀yin ti gbúròó ìgbé ayé mi nígbà àtijọ́ nínú ìsìn àwọn Júù, bí mo tí ṣe inúnibíni sí ìjọ ènìyàn Ọlọ́run rékọjá ààlà, tí mo sì lépa láti bà á jẹ́.
14 V té době snad nebylo mezi mými vrstevníky horlivějšího a pravověrnějšího žida nade mne. Nikdo jiný nehořel pro tradice mého národa tak fanaticky jako já.
Mo sì ta ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi yọ nínú ìsìn àwọn Júù láàrín àwọn ìran mi, mo sì ni ìtara lọ́pọ̀lọ́pọ̀ sì òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn baba mi.
15 Ale pak to přišlo! Bůh mi odhalil pravdu o svém Synu a uložil mi šířit jeho poselství po celém světě. K této službě mne ve své dobrotě vybral již dávno před mým narozením.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ó wú Ọlọ́run ẹni tí ó yà mí sọ́tọ̀ láti inú ìyá mi wá, tí ó sì pé mi nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀.
Láti fi ọmọ rẹ̀ hàn nínú mi, kì èmi lè máa wàásù ìyìnrere rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà; èmi kò wá ìmọ̀ lọ sọ́dọ̀ ẹnikẹ́ni,
17 Když se to stalo, nevyptával jsem se na Krista jiných lidí, ani jsem se nešel radit s jeruzalémskými apoštoly. Odešel jsem do Arábie, vrátil se zase do Damašku
bẹ́ẹ̀ ni èmi kò gòkè lọ sì Jerusalẹmu tọ àwọn tí í ṣe aposteli ṣáájú mi, ṣùgbọ́n mo lọ sí Arabia, mo sì tún padà wá sí Damasku.
18 a teprve po třech letech jsem se vypravil do Jeruzaléma, abych se osobně seznámil s Petrem. Pobyl jsem u něho dva týdny,
Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, nígbà náà ni mo gòkè lọ sì Jerusalẹmu láti lọ kì Peteru, mo sì gbé ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní ìjọ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún,
19 ale kromě Jakuba, Ježíšova bratra, jsem se s dalšími apoštoly nesetkal.
èmi kò ri ẹlòmíràn nínú àwọn tí ó jẹ́ aposteli, bí kò ṣe Jakọbu arákùnrin Olúwa.
20 Tak to skutečně bylo, Bůh je mi svědek, že nelžu.
Nǹkan tí èmi ń kọ̀wé sí yín yìí, kíyèsi i, níwájú Ọlọ́run èmi kò ṣèké.
21 Pak jsem se vydal do Sýrie a Kilikie,
Lẹ́yìn náà mo sì wá sí agbègbè Siria àti ti Kilikia.
22 zatímco v Judsku mě křesťané stále ještě neznali.
Mo sì jẹ́ ẹni tí a kò mọ̀ lójú fún àwọn ìjọ tí ó wà nínú Kristi ni Judea.
23 Věděli jen, že dřívější nepřítel hlásá nyní to, co sám předtím tak krutě potíral,
Wọ́n kàn gbọ́ ìròyìn wí pé, “Ẹni tí ó tí ń ṣe inúnibíni sí wa rí, ní ìsinsin yìí ti ń wàásù ìgbàgbọ́ náà tí ó ti gbìyànjú láti bàjẹ́ nígbà kan rí.”
24 a chválili za to Boha.
Wọ́n sì yin Ọlọ́run lógo nítorí mi.