< Žalmy 83 >

1 Píseň a žalm Azafův. Bože, neodmlčujž se, nečiň se neslyše, aniž se upokojuj, ó Bože silný.
Orin. Saamu ti Asafu. Ọlọ́run, má ṣe dákẹ́; má ṣe dákẹ́, Ọlọ́run má ṣe dúró jẹ́ẹ́.
2 Nebo aj, nepřátelé tvoji se bouří, a ti, kteříž tě v nenávisti mají, pozdvihují hlavy.
Wo bí àwọn ọ̀tá rẹ ti ń rọ́kẹ̀kẹ̀ lọ, bi àwọn ọ̀tá rẹ ti ń gbé ohùn wọn sókè.
3 Chytře tajné rady proti lidu tvému skládají, a radí se proti těm, kteréž ty skrýváš,
Pẹ̀lú àrékérekè ni wọn dìtẹ̀ sí àwọn ènìyàn rẹ; wọn sí dìtẹ̀ mọ́ àwọn tí o fẹ́.
4 Říkajíce: Poďte, a vyhlaďme je, ať nejsou národem, tak aby ani zpomínáno nebylo více jména Izraelova.
Wọn wí pé, “wá, ẹ jẹ́ kí á pa wọ́n run bí orílẹ̀-èdè, kí orúkọ Israẹli ma bá a sí ní ìrántí mọ́.”
5 Jednomyslněť se na tom spolu snesli, i smlouvou se proti tobě zavázali,
Wọ́n gbìmọ̀ pọ̀ pẹ̀lú ọkàn kan; wọ́n ṣe àdéhùn láti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ
6 Stánkové Idumejští a Izmaelitští, Moábští a Agarenští,
Àgọ́ Edomu àti ti àwọn ará Iṣmaeli, ti Moabu àti ti Hagari
7 Gebálští a Ammonitští, a Amalechitští, Filistinští s obyvateli Tyrskými.
Gebali, Ammoni àti Amaleki, Filistia, pẹ̀lú àwọn ènìyàn Tire.
8 Ano i Assyrští spojili se s nimi, jsouce na ruku synům Lotovým. (Sélah)
Asiria pẹ̀lú ti darapọ̀ mọ́ wọn láti ran àwọn ọmọ Lọti lọ́wọ́. (Sela)
9 Učiniž jim jako Madianským, jako Zizarovi, a jako Jabínovi při potoku Císon,
Ṣe sí wọn bí ìwọ ti ṣe sí Midiani bí o ti ṣe sí Sisera àti Jabini ní odò Kiṣoni,
10 Kteříž jsou do konce vyhlazeni v Endor, a učiněni hnůj země.
ẹni tí ó ṣègbé ní Endori tí wọn sì dàbí ààtàn ní orí ilẹ̀.
11 Nalož s nimi a s vůdci jejich jako s Gorébem, jako s Zébem, jako s Zebahem, a jako s Salmunou, se všemi knížaty jejich.
Ṣe àwọn ọlọ́lá wọn bí Orebu àti Seebu, àwọn ọmọ-aládé wọn bí Seba àti Salmunna,
12 Neboť jsou řekli: Uvažme se dědičně v příbytky Boží.
tí ó wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a gbà ní ìní àní pápá oko tútù Ọlọ́run.”
13 Můj Bože, učiň to, ať jsou jako chumelice, a jako stéblo před větrem.
Ìwọ Ọlọ́run, ṣe wọ́n bí ààjà, bí ìyàngbò níwájú afẹ́fẹ́.
14 Jakož oheň spaluje les, a jako plamen zapaluje hory,
Bí iná ti í jó igbó, àti bí ọ̀wọ́-iná ti ń mú òkè ńlá gbiná,
15 Tak ty je vichřicí svou stihej, a bouří svou ohrom je.
bẹ́ẹ̀ ni kí o fi ẹ̀fúùfù líle rẹ lépa wọn dẹ́rùbà wọn lójú pẹ̀lú ìjì rẹ.
16 Naplň tváře jejich zahanbením, tak aby hledali jména tvého, Hospodine.
Fi ìtìjú kún ojú wọn, kí àwọn ènìyàn bá à lè ṣe àfẹ́rí orúkọ rẹ àti kí o fi ìjì líle rẹ dẹ́rùbà, ìwọ Olúwa.
17 Nechať se hanbí a děsí na věčné časy, a ať potupu nesou a zahynou.
Jẹ́ kí ojú kí ó tì wọ́n, kí wọ́n sì dààmú láéláé kí wọ́n ṣègbé sínú ẹ̀gàn
18 A tak ať poznají, že ty, kterýž sám jméno máš Hospodin, jsi nejvyšší nade vší zemí.
jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ìwọ, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa: pé ìwọ nìkan ní Ọ̀gá-ògo jùlọ lórí gbogbo ayé.

< Žalmy 83 >