< Žalmy 142 >

1 Vyučující Davidův, když byl v jeskyni, modlitba jeho. Hlasem svým k Hospodinu volám, hlasem svým Hospodinu pokorně se modlím.
Maskili ti Dafidi. Nígbà tí ó wà nínú ihò òkúta. Àdúrà. Èmi kígbe sókè sí Olúwa; èmi gbé ohùn mi sókè sí Olúwa fún àánú.
2 Vylévám před oblíčejem jeho žádost svou, a ssoužení své před ním oznamuji.
Èmi tú àròyé mí sílẹ̀ níwájú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ní èmi fi iṣẹ́ mi hàn níwájú rẹ̀.
3 Když se úzkostmi svírá ve mně duch můj, ty znáš stezku mou; na cestě, po kteréžkoli chodím, osídlo mi ukryli.
Nígbà tí ẹ̀mí mi ṣàárẹ̀ nínú mi, ìwọ ni ẹni tí ó mọ ọ̀nà mi. Ní ipa ọ̀nà tí èmi ń rìn ènìyàn ti dẹ okùn fún mi ní ìkọ̀kọ̀.
4 Ohlédám-li se na pravo, a patřím, není, kdo by mne znáti chtěl; zhynulo útočiště mé, není, kdo by se ujal o život můj.
Wo ọwọ́ ọ̀tún mi kí ó sì rì i kò sí ẹni tí ó ṣe àníyàn mi èmi kò ní ààbò; kò sí ẹni tí ó náání ọkàn mi.
5 K tobě volám, Hospodine, říkaje: Ty jsi doufání mé a díl můj v zemi živých.
Èmi kígbe sí ọ, Olúwa: èmi wí pé, “Ìwọ ni ààbò mi, ìpín mi ní ilẹ̀ alààyè.”
6 Pozorujž volání mého, neboť jsem zemdlen přenáramně; vysvoboď mne od těch, jenž stihají mne, nebo jsou silnější nežli já.
Fi etí sí igbe mi, nítorí tí èmi wà nínú àìnírètí gbà mí lọ́wọ́ àwọn tí ń lépa mi, nítorí wọ́n lágbára jù mí lọ.
7 Vyveď z žaláře duši mou, abych oslavoval jméno tvé; obstoupí mne spravedliví, když mi dobrodiní učiníš.
Mú ọkàn mi jáde kúrò nínú túbú, kí èmi lè máa yin orúkọ rẹ. Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò yí mi káàkiri nítorí ìwọ yóò fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ba mi ṣe.

< Žalmy 142 >