< Malakhi 3 >
1 Khenhaw! Ka cei nahane lamthung ka rakueng hane ka patoune ka patoun han. Nangmouh ni na tawng awh e Bawipa, na ngaihawi awh e lawkkam e laicei teh amae bawkim dawk tang a tho han. Khenhaw! Hote Bawipa teh a tho lahun ransahu BAWIPA ni a ti.
“Wò ó, Èmi yóò ran ìránṣẹ́ mi, yóò tún ọ̀nà ṣe ṣáájú mi. Nígbà náà ni Olúwa, tí ẹ̀yin ń wa, yóò dé ni òjijì sí tẹmpili rẹ̀; àní oníṣẹ́ májẹ̀mú náà, tí inú yín dùn sí, yóò dé,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
2 A thonae hnin nah apinimaw a khang thai han. A kamnue toteh apimaw kangdout thai han. Bangkongtetpawiteh Bawipa teh ngun sôlêinae hmai hoi a kâvan teh hno pâsunae sapet hoi a kâvan.
Ṣùgbọ́n ta ni o lè fi ara da ọjọ́ dídé rẹ̀? Ta ni yóò sì dúró nígbà tí ó bá fi ara hàn? Nítorí òun yóò dàbí iná ẹni tí ń da fàdákà àti bi ọṣẹ alágbàfọ̀.
3 Ngun hah a sôlêi teh ka thoungsak e ni sui ngun a sôlêi e patetlah Levih miphun a thoungsak dawkvah, ahnimouh teh BAWIPA hanelah kalan e pasoum hno hah a thueng awh han.
Òun yóò sì jókòó bí ẹni tí n yọ́, tí ó sì ń da fàdákà; yóò wẹ àwọn ọmọ Lefi mọ́, yóò sì tún wọn dàbí wúrà àti fàdákà, kí wọn bá a lè mú ọrẹ òdodo wá fún Olúwa,
4 Judah catounnaw hoi Jerusalem khocanaw e pasoum hno hah ayan e kumtha, hnin dawk e patetlah BAWIPA ni a ngai e lah ao han.
nígbà náà ni ọrẹ Juda àti ti Jerusalẹmu yóò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ti ọjọ́ àtijọ́, àti gẹ́gẹ́ bí ọdún ìgbàanì.
5 Nangmouh na tanouk hanelah nangmouh koe ka tho han. Tami ka ân e, ka uicuk e, kamsoumhoehe lah thoe ka kâbo e, aphu poe laipalah ka rektap e, lahmai naranaw ka rektap e, imyinnaw kamsoumhoehe lah lawk ka ceng e, Kai na ka taket hoeh e taminaw e avanglah, kapanuekkhaikung lah tang ka o han telah ransahu BAWIPA ni a ti.
“Èmi ó sì súnmọ́ yin fún ìdájọ́. Èmi yóò sì yára ṣe ẹlẹ́rìí sí àwọn oṣó, sí àwọn panṣágà, sí àwọn abúra èké, àti àwọn tí ó fi ọ̀yà alágbàṣe pọn wọn lójú, àti àwọn tí ó ni àwọn opó àti àwọn aláìní baba lára, àti sí ẹni tí kò jẹ́ kí àjèjì rí ìdájọ́ òdodo gbà, tí wọn kò sì bẹ̀rù mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6 Kai Jehovah teh, kâthungnae awm hoeh. Hatdawkvah Jakop catounnaw nangmouh teh na rawk awh mahoeh.
“Èmi Olúwa kò yípadà. Nítorí náà ni a kò ṣe run ẹ̀yin ọmọ Jakọbu.
7 Mintoenaw koehoi kamtawng teh, nangmouh ni ka phung lawk na tarawi awh hoeh, na roun awh toe. Kai koe bout ban awh haw, kai hai nangmouh koe lah ka ban van han telah ransahu BAWIPA ni ati. Bangtelah hoi maw bout ka ban han na ti awh.
Láti ọjọ́ àwọn baba ńlá yín wá ni ẹ̀yin tilẹ̀ ti kọ ẹ̀yìn sí ìlànà mi, tí ẹ kò sì pa wọ́n mọ́. Ẹ padà wá sí ọ̀dọ̀ mi, Èmi yóò sì padà sí ọ̀dọ̀ yín,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa yóò ṣe padà?’
8 Tami ni Cathut e hno lawp kawi namaw. Hatei, nangmouh ni teh kaie hno na lawp awh toe. Bangtelamaw na lawp awh vaw na tet awh pawiteh, pung hra pung touh thoseh, pasoum hnonaw hai thoseh na lawp awh toe.
“Ènìyàn yóò ha ja Ọlọ́run ni olè bí? Síbẹ̀ ẹ̀yin ti jà mí ní olè. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa ṣe jà ọ́ ní olè?’ “Nípa ìdámẹ́wàá àti ọrẹ.
9 Nangmouh teh thoebo e lah na o awh toe. Bangkongtetpawiteh, khocanaw pueng ni ka hno na lawp awh toe.
Ríré ni a ó fi yín ré: gbogbo orílẹ̀-èdè yìí, nítorí ẹ̀yin ti jà mi lólè.
10 Hra touh dawk buet touh pueng teh hno pâkhuengnae im dawk hmouk awh. Kaie im dawk ca kawi ao nahanelah sak awh. Kalvan tho ka paawng hoi paawng hoeh e, yawhawinae na rabawk sin hoi rabawk sin hoeh e, hottelah hoi na tanouk awh haw telah ransahu BAWIPA ni a ti.
Ẹ mú gbogbo ìdámẹ́wàá wá sí ilé ìṣúra, kí oúnjẹ bá à lè wà ní ilé mi, ẹ fi èyí dán mi wò,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “kí ẹ sì wò bí èmi kò bá ní sí àwọn fèrèsé ọ̀run fún yin, kí èmi sì tú ìbùkún àkúnwọ́sílẹ̀ jáde fún yín, tó bẹ́ẹ̀ tí kì yóò sì ààyè láti gbà á.
11 Na talai dawk e a pawhiknaw hah ahriainaw koe ka raphoe sak mahoeh. Nangmae misurkung teh a paw paw laipalah awm mahoeh telah ransahu BAWIPA ni a ti.
Èmi yóò sì bá kòkòrò ajẹnirun wí nítorí yín, òun kò sì ni run èso ilẹ̀ yín, bẹ́ẹ̀ ni àjàrà inú oko yín kò ní rẹ̀ dànù,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
12 Miphun pueng ni nangmouh teh a yaw kahawi e tami telah na kaw awh han. Na ram hai ngai kaawm e ram lah ao han telah ransahu BAWIPA ni a ti.
“Nígbà náà ni gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sì pè yín ni alábùkún fún, nítorí tiyín yóò jẹ́ ilẹ̀ tí ó wu ni,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
13 BAWIPA koe lawk kahram lahoi na dei awh nahlangva vah, nangmouh ni bangtelamaw ka dei payon awh vaw, khuet na ti awh vaw.
“Ẹ̀yin ti sọ ọ̀rọ̀ líle sí mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Síbẹ̀ ẹ̀yin béèrè pé, ‘Ọ̀rọ̀ kín ni àwa sọ sí ọ?’
14 Cathut e thaw ka tawk nakunghai ahawinae awm hoeh. Cangkhai e naw ka tarawi awh teh, ransahu BAWIPA hmalah rawca ka hai awh nakunghai bangmaw ahawinae kaawm.
“Ẹ̀yin ti wí pé, ‘Asán ni láti sin Ọlọ́run. Kí ni àwa jẹ ní èrè, nígbà tí àwa ti pa ìlànà rẹ mọ́, tí àwa sì ń rìn kiri bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ní iwájú Olúwa àwọn ọmọ-ogun?
15 Ka kâoup e taminaw hah a yaw kahawi e taminaw telah kaimouh ni ka ti awh. Atangcalah, yonnae ka saknaw law teh a tawnta awh. Cathut a tanouk nakunghai a hlout awh telah na ti awh.
Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí àwa pé agbéraga ni alábùkún fún. Ní òtítọ́ ni àwọn ti ń ṣe búburú ń gbèrú sí i, kódà àwọn ti ó dán Ọlọ́run wò ni a dá sí.’”
16 Hatnavah BAWIPA kabarinaw teh buet touh hoi buet touh a kâpato awh. BAWIPA ni hai a hnâpakeng teh a thai pouh. BAWIPA ka taket ni teh a min alawkpui lah ka tat e taminaw teh, a hmalah cayin a pakhum pouh.
Nígbà náà ni àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa ń ba ara wọn sọ̀rọ̀, Olúwa sì tẹ́tí sí i, ó sì gbọ́. A sì kọ ìwé ìrántí kan níwájú rẹ̀, fún àwọn tí o bẹ̀rù Olúwa, tiwọn sì bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ̀.
17 Ahnimanaw teh lawk ka ceng hnin vah ka coe e hno lah ao awh han. A na pa e thaw ka tawk e capa hah na pa ni pasai e patetlah ahnimanaw hah ka pasai han telah ransahu BAWIPA ni a ti.
“Wọn yóò sì jẹ́ tèmi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “ni ọjọ́ náà, tí èmi ó dá; èmi yóò sì da wọ́n sí gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí máa ń dá ọmọ rẹ̀ tí yóò sìn ín sí.
18 Hahoi, nangmouh teh, na lung a kâthung awh teh kalan e tami, kalan hoeh e tami, Cathut e thaw ka tawk e tami, ka tawk hoeh e taminaw hah na panue awh han.
Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rí ìyàtọ̀, ìyàtọ̀ láàrín olódodo àti ẹni búburú, láàrín ẹni tí ń sìn Ọlọ́run, àti ẹni tí kò sìn ín.