< Lampahnah 32 >
1 Te vaengah Reuben ca rhoek te boiva muep om tih Gad ca taengah khaw ping uh khungdaeng. Te phoeiah Jazer khohmuen neh Gilead khohmuen te a sawt vaengah a hmuen khaw boiva hmuen la tarha a hmuhuh.
Àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, tí wọ́n ní ẹran ọ̀sìn àti ohun ọ̀sìn rí wí pé ilẹ̀ Jaseri àti Gileadi dára fún ohun ọ̀sìn.
2 Te dongah Gad koca rhoek neh Reuben koca rhoek te cet uh tih Moses taeng neh khosoih Eleazar taengah khaw, rhaengpuei khoboei rhoek taengah khaw a thui uh.
Àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni sì wá, wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Eleasari àlùfáà àti sí olórí gbogbo ìlú, wọ́n sì wí pé,
3 Te vaengah Ataroth neh Dibon, Jazer neh Nimrah, Heshbon neh Elealeh, Sibam, Nebo, Beon,
“Atarotu, Diboni, Jaseri, Nimra, Heṣboni, Eleale, Sebamu, Nebo, àti Beoni.
4 Isreal rhaengpuei kah mikhmuh ah BOEIPA loh a ngawn khohmuen te boiva kah khohmuen tih na sal rhoek taengah khaw boiva om ta,” a ti uh.
Ni ilẹ̀ tí Olúwa ti ṣẹ́gun níwájú ìjọ Israẹli tí ó sì dára fún ohun ọ̀sìn, ṣáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì ní ohun ọ̀sìn.”
5 Te phoeiah, “Na mik ah mikdaithen ka hmuh atah he khohmuen he na sal rhoek taengah khohut la m'paek vetih Jordan te kaimih nam paan sak pawt mako,” a ti uh.
Wọ́n wí pé, “Tí a bá rí ojúrere rẹ, jẹ́ kí a fi ilẹ̀ yìí fún ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìní. Má ṣe jẹ́ kí a rékọjá odò Jordani.”
6 Tedae Moses loh Gad koca rhoek taeng neh Reuben koca rhoek taengah, “Nangmih hela na ngol uh vaengah na manuca rhoek tah caemtloek la cet uh saeh a?
Mose sọ fún àwọn ọmọ Gadi àti fún ọmọ Reubeni pé, “Ṣé kí àwọn arákùnrin yín lọ sí ogun, kí ẹ̀yin kí ó sì jókòó sí bí?
7 BOEIPA loh amih taengah a paek khohmuen la kat ham te balae tih Israel ca rhoek kah lungbuei he a khaban la na khaban uh.
Kí ni ó dé tí o fi mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti lọ sí ibi ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn?
8 Khohmuen sawt ham Kadeshbarnea lamloh amih ka tueih vaengah na pa rhoek loh he ni a saii uh.
Èyí ni nǹkan tí baba yín ṣe nígbà tí mo rán wọn láti Kadeṣi-Barnea láti lọ wo ilẹ̀ náà.
9 Eshkol soklong la cet uh tih khohmuen khaw a hmuh uh dae BOEIPA loh amih taengah a paek khohmuen la kun pawt ham Israel ca rhoek kah lungbuei te a khaban uh.
Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n lọ sí àfonífojì Eṣkolu tí wọ́n rí ilẹ̀ náà, wọ́n mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti wọ ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn.
10 Amah khohnin ah BOEIPA kah thintoek sai tih a toemngam.
Ìbínú Olúwa sì dìde sí wọn ní ọjọ́ náà, ó sì búra, wí pé,
11 Egypt lamkah aka lo hlang rhoek khuiah kum kul neh a so hang ca rhoek tah khohmuen te hmu uh mahpawh. Te te Abraham, Isaak taeng neh Jakob taengah ka toemngam dae kai hnukah a tlun uh moenih.
‘Nítorí wọn kò tẹ̀lé mi tọkàntọkàn, kì í ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin náà tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ó gòkè láti Ejibiti ni yóò rí ilẹ̀ tí mo pinnu gẹ́gẹ́ bí ìbúra fún Abrahamu, fún Isaaki àti fún Jakọbu:
12 Kenizzi Jephunneh capa Kaleb neh Nun capa Joshua tah BOEIPA hnukah tlun rhoi.
kò sí ẹnìkankan àyàfi Kalebu ọmọ Jefunne ti Kenissiti àti Joṣua ọmọ Nuni, nítorí wọ́n tẹ̀lé Olúwa tọkàntọkàn.’
13 Te vaengah BOEIPA kah thintoek te Israel taengah sai tih BOEIPA mik ah boethae aka saii kah cadil boeih a cing hil amih te khosoek ah kum sawmli a poengdoe sak.
Ìbínú Olúwa ru sí àwọn ọmọ Israẹli ó sì mú wọn rìn ní aginjù fún ogójì ọdún, títí tí àwọn ìran tí wọ́n ṣe búburú ní ojú rẹ̀ fi lọ.
14 Israel taengah BOEIPA kah thintoek thinsa te koep khoengvoep ham ni na pa rhoek yueng hlangtholh hlang kah tahoengnah dongah na pai uh he.
“Níbí ni ẹ̀yin wà, ẹ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀, ẹ̀yin dìde ní ipò baba yín, ẹ sì jẹ́ kí ìbínú gbígbóná Olúwa ru sí Israẹli.
15 A hnuk lamloh na phael uh dongah khosoek ah amih tloeng ham koep a koei vetih he pilnam boeih he na mit uh bitni,” a ti nah.
Tí ẹ̀yin bá yípadà ní ẹ̀yìn rẹ̀ yóò sì fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí sílẹ̀ ní aginjù, ìwọ yóò sì mú un ṣe ìparun.”
16 Te phoeiah a taengla mop uh tih, “Kaimih kah boiva ham boiva kah tanglung neh ka ca rhoek ham khopuei pahoi ka thoh uh mako.
Nígbà náà wọ́n wá sí òkè ní ọ̀dọ̀ rẹ̀, “Àwa yóò fẹ́ láti kọ́ ilé ẹran níhìn-ín yìí fún ohun ọ̀sìn wa, àti ìlú fún àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa.
17 Tedae amih te a hmuen la ka pawk uh hil tah kaimih he Israel ca mikhmuh ah tawn uh ham ka pumcum uh bitni. Te vaengah khohmuen kah khosa rhoek mikhmuh lamkah hmuencak khopuei rhoek ah mamih kah camoe rhoek ana om saeh.
Ṣùgbọ́n àwa ṣetán láti dira ogun ṣáájú àwọn ọmọ Israẹli títí tí a yóò fi mú wọn dé ọ̀dọ̀ wọn lákokò yìí, àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa yóò gbé inú ìlú tí a mọ odi sí fún ìdáàbòbò wọn lọ́wọ́ olùgbé ilẹ̀ náà.
18 Israel ca rhoek khuikah hlang loh a rho a pang hlanah ka im la ka mael uh mahpawh.
A kì yóò padà sí ilẹ̀ wa láìṣe pé gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti gba ogún wọn.
19 Jordan kah rhalvangan neh a voel kah amih neh m'phaeng uh boel saeh. Jordan khocuk ngan ah kaimih taengah kamamih kah rho om coeng,” a ti uh.
A kì yóò gba ogún kankan pẹ̀lú wọn ní òdìkejì Jordani, nítorí ogún ti wa, ti wá sí ọ̀dọ̀ wa ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani.”
20 Te dongah Moses loh amih te, “He ol he na ngai uh mak atah, caemtloek ham BOEIPA mikhmuh ah na pumcum uh mak atah,
Nígbà náà ni Mose sọ fún wọn pé, “Tí ẹ̀yin yóò bá pa ara yín lára, níwájú Olúwa fún ogún.
21 Nangmih aka pumcum boeih te tah BOEIPA mikhmuh ah Jordan te a poeng vetih a thunkha rhoek te a mikhmuh lamloh a haek ni.
Bí gbogbo yín yóò bá lọ sí Jordani ní ìhámọ́ra níwájú Olúwa, títí yóò fi lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ kúrò níwájú rẹ̀.
22 BOEIPA mikhmuh ah khohmuen a khoem uh coeng. Te dongah mael uh lamtah BOEIPA taeng neh Israel taengah ommongsitoe la na om uh bitni. Khohmuen he BOEIPA mikhmuh ah nangmih kah khohut la om bitni.
Tí a ó sì fi ṣe ilẹ̀ náà níwájú Olúwa; ẹ̀yin lè padà tí yóò sì di òmìnira lọ́wọ́ ìdè níwájú Olúwa àti Israẹli. Ilẹ̀ yìí yóò sì jẹ́ tiyín níwájú Olúwa.
23 Te te na saii uh pawt atah BOEIPA taengah na tholh coeng ne. Te vaengah namamih kah tholhnah loh nangmih m'hmuh bitni tila ming uh.
“Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kọ̀ láti ṣe èyí, ẹ̀yin yóò máa dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa; kí ẹ̀yin kí ó sì mọ̀ dájú pé ẹ̀ṣẹ̀ yín yóò fi yín hàn.
24 Nangmih ham neh na camoe ham khopuei khaw, na tu ham tanglung khaw thoh uh. Tedae nangmih ka lamloh aka thoeng te rhoi uh,” a ti nah.
Ẹ kọ́ ilé fún àwọn obìnrin yín àti ọmọ wẹ́wẹ́ yín, àti ilé fún agbo ẹran yín, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin kí ó ṣe ohun tí ẹ ti pinnu.”
25 Te phoeiah Gad koca rhoek neh Reuben koca rhoek loh Moses taengah, “Na sal rhoek long he ka boei kah a uen bangla a saii uh bitni.
Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni sọ fún Mose pé, “Àwa ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti pàṣẹ.
26 Ka yuu rhoek neh ka ca rhoek, ka boiva neh ka rhamsa boeih tah Gilead khopuei rhoek ah pahoi om uh bitni.
Àwọn ọmọ wa àti ìyàwó wa, àwọn agbo ẹran àti ohun ọ̀sìn wa yóò dúró ní ìlú Gileadi.
27 Ka boei kah na thui bangla, BOEIPA mikhmuh ah caempuei la aka pumcum na sal rhoek tah caemtloek la boeih kat bitni ni,” a ti uh.
Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra ogun, yóò rékọjá lọ láti jà níwájú Olúwa; gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti sọ.”
28 Amih kongah Moses loh khosoih Eleazar, Nun capa Joshua neh Israel ca rhoek kah koca, a napa boeilu rhoek te a uen.
Nígbà náà ni Mose pàṣẹ nípa wọn fún Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni àti sí gbogbo olórí ìdílé ẹ̀yà Israẹli.
29 Te vaengah Moses loh amih te, “BOEIPA mikhmuh ah caemtloek la aka pumcum Gad koca rhoek neh Reuben ca boeih tah nangmih taengah Jordan te kat uh coeng. Nangmih mikhmuh ah khohmuen te a khoem uh dongah Gilead khohmuen te amih taengah khohut la pae.
Mose sì wí fún wọn pé, “Tí àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra fún ogun rékọjá odò Jordani pẹ̀lú níwájú Olúwa, nígbà tí ẹ ṣẹ́gun ilẹ̀ náà níwájú yín, fún wọn ní ilẹ̀ Gileadi gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
30 Nangmih taengah aka pumcum uh khaw a kat uh pawt atah Kanaan khohmuen ah tah nangmih khui kah te bawn uh saeh,” a ti nah.
Ṣùgbọ́n tí wọn kò bá fẹ́ bá yín rékọjá pẹ̀lú ìhámọ́ra, wọn gbọdọ̀ gba ìní wọn pẹ̀lú yín ní Kenaani.”
31 Gad koca rhoek neh Reuben koca rhoek loh a doo uh tih, “BOEIPA loh na sal rhoek taengah a thui bangla ka saii uh tangloeng bitni.
Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni dáhùn pé, “Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe ohun tí Olúwa ti sọ.
32 Kaimih BOEIPA mikhmuh ah aka pumcum rhoek tah Kanaan khohmuen la ka kat uh ni. Tedae Jordan rhalvang he tah kaimih kah rho neh kaimih ham khohut la om saeh,” a ti uh.
A máa rékọjá níwájú Olúwa lọ sí Kenaani pẹ̀lú ìhámọ́ra, ṣùgbọ́n ẹrù tí a jogún yóò wà ní ẹ̀bá Jordani.”
33 Te dongah Moses loh amih, Gad koca rhoek taeng neh Reuben koca rhoek taengah khaw, Joseph capa Manasseh koca hlangvang taengah khaw, Amori manghai Sihon kah ram, Bashan manghai Oga kah ram neh khohmuen, khohmuen kaepvai khopuei rhibawn kah a khopuei te a paek.
Nígbà náà Mose fún àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu ní ilẹ̀ ọba Sihoni ọba àwọn ọmọ Amori àti ilẹ̀ ọba Ogu ọba Baṣani ní gbogbo ilẹ̀ náà pẹ̀lú ìlú rẹ̀ àti agbègbè tí ó yí i ka.
34 Te dongah Gad koca rhoek loh, Dibon, Ataroth neh Aroer,
Àwọn ará Gadi wọ́n kọ́ Diboni, Atarotu, Aroeri;
35 Aroth-shonphan, Jazer neh Jobehah,
pẹ̀lú Atrotu Ṣofani, Jaseri, àti Jogbeha,
36 Bethnimrah neh Bethharan, hmuencak khopuei rhoek neh boiva kah tanglung te a thoh uh.
pẹ̀lú Beti-Nimra, àti Beti-Harani ìlú olódi, àti agbo fún àgùntàn.
37 Reuben koca rhoek loh Heshbon, Elealeh neh Kiriathaim,
Àwọn ọmọ Reubeni sì kọ́ Heṣboni, Eleale, Kiriataimu,
38 Nebo neh ming aka hoi Baalmeon, Sibam te a thoh uh. Te kah a thoh uh khopuei rhoek ming te a ming neh a khue uh.
pẹ̀lú Nebo pẹ̀lú Baali-Meoni (wọ́n pàrọ̀ orúkọ wọn) àti Sibma. Wọ́n sì sọ ìlú tí wọ́n tún kọ́ ní orúkọ mìíràn.
39 Manasseh capa Makir koca rhoek tah Gilead la cet uh tih a buem uh. Te vaengah a khui kah Amori te a haek uh.
Àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase lọ sí Gileadi, wọ́n sì lé àwọn ọmọ Amori tí ó wà níbẹ̀.
40 Te dongah Moses loh Gilead te Manasseh capa Makir taengah a paek tih a khuiah kho a sak uh.
Mose sì fi àwọn ọmọ Gileadi fún àwọn ọmọ Makiri àwọn ìran Manase, wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.
41 Manasseh capa Jair loh cet tih a vangca rhoek te loh dongah te rhoek te Jair vangca a sui.
Jairi, ọmọ Manase gba ibùjókòó wọn, ó sì pè wọ́n ní Haffotu Jairi.
42 Nobah khaw cet tih Kenath neh a khobuel rhoek te a loh. Te dongah te te amah ming la Nobah a sui.
Noba gba Kenati àti àwọn ìtẹ̀dó rẹ̀, ó sì pè é ní Noba lẹ́yìn orúkọ ara rẹ̀.