< Jeremiah 29 >

1 He cabu ol he Jerusalem lamkah tonghma Jeremiah loh vangsawn patong hlangrhuel taeng neh khosoih rhoek taeng neh, tonghma rhoek taeng neh, Nebukhanezar loh Jerusalem lamkah Babylon duela a poelyoe pilnam boeih taengah,
Èyí ni ọ̀rọ̀ inú lẹ́tà tí wòlíì Jeremiah rán láti Jerusalẹmu sí ìyókù nínú àwọn àgbàgbà tí ó wà ní ìgbèkùn àti sí àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo àwọn ènìyàn tí Nebukadnessari tí kó ní ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
2 Manghai Jekoniah neh manghainu, Judah tildit mangpa rhoek neh Jerusalem rhoek, Jerusalem kah kutthai rhoek neh thidae rhoek a khuen phoeiah tah,
Lẹ́yìn ìgbà tí Jekoniah, ọba, àti ayaba, àti àwọn ìwẹ̀fà, àti àwọn ìjòyè Juda àti Jerusalẹmu, àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà àti àwọn olùyàwòrán tí wọ́n lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu.
3 Shaphan capa Elasah neh Hilkiah capa Gemariah kut dongah a pat. Amih rhoi te Babylon manghai Nebukhanezar taengkah Judah manghai Zedekiah taengah Babylon la a tueih tih,
Ó fi lẹ́tà náà rán Eleasa ọmọ Ṣafani àti Gemariah ọmọ Hilkiah, ẹni tí Sedekiah ọba Juda rán sí Nebukadnessari ọba Babeli. Wí pé.
4 Israel Pathen caempuei BOEIPA loh he ni a thui. vangsawn boeih te Jerusalem lamloh Babylon la ka poelyoe coeng.
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn tí mo kó lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu ní Babeli:
5 Im thoh uh lamtah khosa uh, dum tue uh lamtah a thaih te ca uh.
“Ẹ kọ́ ilé kí ẹ sì máa gbé ibẹ̀, ẹ dá oko, kí ẹ sì máa jẹ èso ohun ọ̀gbìn oko yín.
6 Yuu lo uh lamtah canu neh capa cun uh. Na capa ham khaw yuu loh pah lamtah na canu te a va taengah pae. Te daengah ni canu neh capa a sak uh vetih a ping uh pahoi neh na muei uh pawt eh.
Ẹ ṣe ìgbéyàwó, kí ẹ sì bí ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin, ẹ gbé ìyàwó fún àwọn ọmọkùnrin yín, kí ẹ sì fi àwọn ọmọbìnrin yín fún ọkọ. Kí àwọn náà lè ní ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. Ẹ máa pọ̀ sí i ní iye, ẹ kò gbọdọ̀ dínkù ní iye níbẹ̀ rárá.
7 Te lam te nangmih kam poelyoe akhaw khopuei kah ngaimongnah mah toem uh. Te ham te BOEIPA taengah thangthui uh lamtah a ngaimongnah dongah nangmih ham ngaimongnah om bitni.
Bákan náà, ẹ máa wá àlàáfíà àti ìre ìlú, èyí tí mo kó yín lọ láti ṣe àtìpó. Ẹ gbàdúrà sí Olúwa fún ìre ilẹ̀ náà; nítorí pé bí ó bá dára fún ilẹ̀ náà, yóò dára fún ẹ̀yin pẹ̀lú.”
8 Israel Pathen caempuei BOEIPA loh he ni a thui. Nangmih khui kah na tonghma rhoek neh nangmih taengkah bihma rhoek loh nangmih te n'rhaithi boel saeh. Na mang na man uh te khaw hnatung uh boeh.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: “Ẹ má ṣe gbà kí àwọn wòlíì èké àti àwọn aláfọ̀ṣẹ àárín yín tàn yín jẹ. Ẹ má ṣe fetísílẹ̀ sí àlá, èyí tí ẹ gbà wọ́n níyànjú láti lá.
9 Amih te kan tueih pawt dae nangmih taengah tah kai ming neh a honghi lam ni a tonghma uh. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún yín lórúkọ mi, Èmi kò rán wọn níṣẹ́,” ni Olúwa wí.
10 He tah BOEIPA long ni a thui. Ka ka dongkah he Babylon ham soep ni. Kum sawmrhih vaengah nangmih kang hip vetih he hmuen la nangmih te mael puei ham ka ol then he nangmih soah ka thoh ni.
Báyìí ni Olúwa wí: “Nígbà tí ẹ bá lo àádọ́rin ọdún pé ní Babeli, èmi yóò tọ̀ yín wá láti ṣe àmúṣẹ ìlérí ńlá mi fún un yín, àní láti kó o yín padà sí Jerusalẹmu.
11 Nangmih ham ka poek, kopoek te khaw ka ming ngawn. He tah BOEIPA kah olphong coeng ni. Ngaimong kopoek neh nangmih taengah hmailong ngaiuepnah paek ham te yoethaenah ham moenih.
Nítorí mo mọ èrò tí mo rò sí yín,” ni Olúwa wí, “àní èrò àlàáfíà, kì í sì ṣe fún ibi, èrò láti fún un yín ní ìgbà ìkẹyìn àti ìrètí ọjọ́ iwájú.
12 Te vaengah kai he nan khue uh vetih na pongpa uh ni. Kai taengah na thangthui uh vaengah nangmih taengkah ka hnatun ni.
Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò ké pè mí, tí ẹ̀yin yóò sì gbàdúrà sí mi, tí èmi yóò sì gbọ́ àdúrà yín.
13 Kai nan tlap uh vaengah nan hmuh uh bitni. Te vaengah na thinko boeih neh kai nan toem uh mako ne.
Ẹ̀yin yóò wá mi, bí ẹ̀yin bá sì fi gbogbo ọkàn yín wá mi: ẹ̀yin yóò rí mi ni Olúwa Ọlọ́run wí.
14 Nangmih te kan hmuh bitni. He tah BOEIPA kah olphong coeng ni. Nangmih khuikah thongtla, thongtla te ka mael sak vetih namtom boeih lamkah neh nangmih kang heh nah hmuen boeih lamloh nangmih te kan coi. He tah BOEIPA kah olphong ni. Nangmih kam poelyoe hmuen lamloh nangmih te kam mael puei ni.
Èmi yóò di rí rí fún yín ni Olúwa wí, Èmi yóò sì mú yín padà kúrò ní ìgbèkùn. Èmi yóò ṣà yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè àti ibi gbogbo tí Èmi ti lé yín jáde, ni Olúwa wí. Èmi yóò sì kó yín padà sí ibi tí mo ti mú kí a kó yín ní ìgbèkùn lọ.”
15 'BOEIPA loh mamih ham Babylon ah tonghma a phoe,’ na ti uh.
Ẹ̀yin lè wí pé, “Olúwa ti gbé àwọn wòlíì dìde fún wa ní Babeli.”
16 Tedae BOEIPA loh David kah ngolkhoel dongah aka ngol manghai kawng neh he khopuei kah khosa pilnam boeih kah a kawng, nangmih neh vangsawn la aka cet pawh na manuca kawng ni a thui tangkhuet.
Ṣùgbọ́n èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa ní ti ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi àti ní ti gbogbo ènìyàn tó ṣẹ́kù ní ìlú yìí; àní ní ti àwọn ènìyàn yín tí kò bá yín lọ sí ìgbèkùn,
17 Caempuei BOEIPA loh he ni a thui. Kai loh amih taengah cunghang, khokha neh duektahaw khaw ka tueih coeng ke. Amih te thaibu thaihuk bangla ka khueh vetih a thaenah te ca uh thai mahpawh.
bẹ́ẹ̀ ni, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí àárín wọn; Èmi yóò ṣe wọ́n bí èso ọ̀pọ̀tọ́ búburú tí kò ṣe é jẹ.
18 Amih hnukah cunghang neh, khokha neh, duektahaw neh ka hloem vetih tonganah neh ngaihuetnah la, diklai ram boeih taengah thaephoeinah la, imsuep la, thuithetnah la, amih ka heh nah namtom boeih taengah kokhahnah la amih te ka khueh ni.
Èmi yóò fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn lépa wọn, Èmi yóò sì sọ wọ́n di ìríra lójú gbogbo ìjọba ayé, fún ègún, àti ìyanu, àti ẹ̀sín, àti ẹ̀gàn láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, ní ibi tí Èmi yóò lé wọn sí.
19 Ka ol he a hnatun uh moenih te. He tah BOEIPA kah olphong ni. Amih taengah ka sal tonghma rhoek te kan tueih. A thoh neh kan tueih akhaw na hnatun uh moenih. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Nítorí wọ́n kọ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,” ni Olúwa Ọlọ́run wí. Ọ̀rọ̀ tí mo tún ti ẹnu àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì sọ ní ẹ̀yin tí ń ṣe àtìpó kò gbọ́ ni Olúwa Ọlọ́run wí.
20 Te dongah Jerusalem lamloh Babylon la ka tueih nangmih vangsawn boeih loh BOEIPA ol he hnatun uh.
Nítorí náà, gbogbo ẹ̀yin ìgbèkùn, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin tí mo rán lọ kúrò ní Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
21 Israel Pathen caempuei BOEIPA loh Kolaiah capa Ahab neh Maaseiah capa Zedekiah kawng, kai ming neh nangmih taengah a honghi la aka tonghma rhoek he a thui. Amih te Babylon manghai Nebukhanezar kut dongah ka tloeng coeng tih nangmih mikhmuh ah amih te a ngawn ni.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli sọ nípa Ahabu ọmọ Kolaiah àti nípa Sedekiah ọmọ Maaseiah tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún un yín lórúkọ mi: “Èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́. Òun yóò sì gba ẹ̀mí wọn ní ìṣẹ́jú yìí gan an.
22 Amih kongah Babylon kah Judah hlangsol boeih loh rhunkhuennah la lo uh saeh. “Babylon manghai loh amih rhoi Zedekiah neh Ahab te hmai neh a rhoh bangla BOEIPA loh nang n'khueh,” ti saeh.
Nítorí tiwọn, ègún yìí yóò ran gbogbo àwọn àtìpó tó wà ní ilẹ̀ Babeli láti Juda: ‘Olúwa yóò ṣe yín bí i Sedekiah àti Ahabu tí ọba Babeli dáná sun.’
23 Israel taengah boethaehalang a saii uh tih a hui kah yuu nen khaw samphaih uh. Amih ka uen pawt mai ah kai ming neh a honghi ol a thui uh. Kai laipai long he ka ming khaw ka ming ta. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Nítorí wọ́n ti ṣe ibi ní ilé Israẹli, wọ́n ti ṣe àgbèrè pẹ̀lú àwọn ìyàwó aládùúgbò wọn, àti ní orúkọ mi ni wọ́n ti ṣe èké, èyí tí Èmi kò rán wọn láti ṣe. Ṣùgbọ́n, Èmi mọ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo sì jẹ́ ẹlẹ́rìí sí i,” ni Olúwa wí.
24 Nehelam Shemaiah te khaw thui pah.
Wí fún Ṣemaiah tí í ṣe Nehalami pé,
25 He ni Israel Pathen, caempuei BOEIPA loh a thui. Namah loh na ming neh Jerusalem kah pilnam boeih taengah, Maaseiah capa khosoih Zephaniah taeng neh khosoih boeih taengah ca pat lamtah thui pah,” ti nah.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli wí: Ìwọ fi lẹ́tà ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ènìyàn ní Jerusalẹmu sí Sefaniah ọmọ Maaseiah tí í ṣe àlùfáà ní orúkọ mi; ó sì sọ fún Sefaniah wí pé,
26 BOEIPA loh khosoih Jehoiada yueng BOEIPA im kah hlangtawt la om ham khosoih la nang n'khueh coeng. Pavai neh tonghma hlang boeih te hloong khui neh thi rhawnmoep dongla khueh nawn.
‘Olúwa ti yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àlùfáà rọ́pò Jehoiada láti máa jẹ́ alákòóso ilé Olúwa, kí o máa fi èyíkéyìí nínú àwọn aṣiwèrè tó bá ṣe bí i wòlíì si inú àgò irin.
27 Te dongah balae tih nangmih taengah aka tonghma Anatoth Jeremiah te na tluung laeh pawh?
Nítorí náà, èéṣe tí o kò fi bá Jeremiah ará Anatoti wí. Ẹni tí ó ń dúró bí i wòlíì láàrín yín?
28 He dongah nim Babylon kah mamih ham ol han tah. Im te puet thoh uh lamtah khosa uh, dum tue uh lamtah a thaih te ca uh a ti rhailai,'ti nah,” a ti.
Ó ti rán iṣẹ́ yìí sí wa ni Babeli wí pé, àtìpó náà yóò pẹ́ kí ó tó parí, nítorí náà, ẹ kọ́ ilé kí ẹ sì máa gbé ibẹ̀, ẹ dá oko, kí ẹ sì máa jẹ èso ohun ọ̀gbìn oko yín.’”
29 Tedae tekah cabu te khosoih Zephaniah loh tonghma Jeremiah kah a hna ah a tae pah.
Sefaniah àlùfáà ka lẹ́tà náà sí etí ìgbọ́ Jeremiah tí í ṣe wòlíì.
30 Te vaengah BOEIPA ol te Jeremiah taengla ha pawk.
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé,
31 vangsawn boeih taengah thui hamla tueih laeh. Nehelam Shemaiah kawng ni BOEIPA loh a thui coeng he. Shemaiah te nangmih taengah tonghma ngawn cakhaw kai loh anih kan tueih pawt dongah nangmih te a honghi dongah ni m'pangtung sak.
“Rán iṣẹ́ yìí sí gbogbo àwọn ìgbèkùn wí pé: ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí ní ti Ṣemaiah, ará Nehalami: Nítorí pé Ṣemaiah ti sọtẹ́lẹ̀ fún un yín, ṣùgbọ́n èmi kò ran an, tí òun sì ń mú u yín gbẹ́kẹ̀lé èké.
32 Te dongah BOEIPA loh he ni a thui. Nehelam Shemaiah neh a tiingan te ka cawh coeng. Anih te he pilnam lakli ah hlang hing la om pawt vetih ka pilnam taengah a then ka saii te khaw hmu mahpawh. He tah BOEIPA kah olphong ni. Anih loh BOEIPA taengah koeknah ni a thui.
Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: Wò ó, èmi yóò bẹ Ṣemaiah, ará Nehalami wò, àti irú-ọmọ rẹ̀; òun kì yóò ní ọkùnrin kan láti máa gbé àárín ènìyàn yìí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò rí rere náà tí èmi yóò ṣe fún àwọn ènìyàn mi ni Olúwa wí, nítorí ó ti ti kéde ìṣọ̀tẹ̀ sí mi.’”

< Jeremiah 29 >