< Ezekiel 48 >

1 Koca rhoek kah a ming he tlangpuei khobawt lamloh Lebokhamat kah Hethlon longpuei kah ngolbuel taeng duela, Damasku khorhi kah Hazarenan tlangpuei la, Khamath ngolbuel phai neh tuipuei kah khothoeng baengki hil te pakhat ah Dan rhoek om uh saeh.
“Ìwọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà tí a kọ sílẹ̀ pẹ̀lú orúkọ wọn: “Ní òpin àríwá, Dani yóò ni ìpín kan; èyí yóò tẹ̀lé ọ̀nà Hetiloni lọ sí Lebo-Hamati; Hasari-Enani àti ààlà àríwá tí Damasku tí ó kángun sí Hamati yóò jẹ́ ara ààlà rẹ̀ láti ìhà ìlà-oòrùn títí lọ sí ìhà ìwọ̀-oòrùn.
2 Dan khorhi dongah khothoeng saa lamloh khotlak baengki due pakhat ah Asher ham saeh.
Aṣeri yóò ní ìpín kan; yóò jẹ́ ààlà agbègbè Dani láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn.
3 Asher khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te pakhat ah Naphtali ham saeh.
Naftali yóò ní ìpín kan; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Aṣeri láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn.
4 Naphtali khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil pakhat ah Manasseh ham saeh.
Manase yóò ní ìpín; èyí yóò jẹ́ ààlà ti agbègbè Naftali láti ìlà-oòrùn sí ìwọ̀-oòrùn.
5 Manasseh khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te pakhat ah Ephraim ham saeh.
Efraimu yóò ní ìpín kan; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Manase láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn.
6 Ephraim khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te pakhat ah Reuben ham saeh.
Reubeni yóò ní ìpín kan; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Efraimu láti ìlà-oòrùn títí dé ìwọ̀-oòrùn.
7 Reuben khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te pakhat ah Judah ham saeh.
Juda yóò ní ìpín kan; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Reubeni láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn.
8 Judah khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil khosaa om saeh. Te te a daang neh a yun thawng kul thawng nga tloeng uh. Khothoeng baengki lamloh khotlak baengki duela khoyo pakhat la om saeh lamtah a khui ah rhokso om saeh.
“Ní agbègbè Juda, láti ìhà ìlà-oòrùn dé ìhà ìwọ̀-oòrùn ni yóò jẹ́ ìpín tí ìwọ yóò gbé kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn pàtàkì. Èyí tí yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní ìbú, gígùn rẹ̀ láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn yóò jẹ́ bákan náà bí ọ̀kan nínú àwọn ìpín ìyókù; láti ìhà ìlà-oòrùn dé ìhà ìwọ̀-oòrùn, ibi mímọ́ yóò sì wà ní àárín gbùngbùn rẹ̀.
9 BOEIPA taengah khosaa te a yun thawng kul thawng nga neh a daang thawng rha na tloeng ni.
“Ìpín pàtàkì tí ìwọ yóò fi fún Olúwa yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ní gígùn àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú.
10 He rhoek he khosoih rhoek ham khosaa hmuencim la om ni. Tlangpuei ah thawng kul thawng nga, khotlak ah a daang te thawng rha saeh lamtah khothoeng ah a daang thawng rha saeh, tuithim ah a yun thawng kul thawng nga neh a khui ah BOEIPA kah rhokso om saeh.
Èyí yóò jẹ́ ìpín ibi mímọ́ fún àwọn àlùfáà. Èyí yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn ní ìhà àríwá, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ ni ìhà ìlà-oòrùn, ó sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn ní ìhà gúúsù. Ní àárín gbùngbùn rẹ̀ ní ilé fún Olúwa yóò wà.
11 Zadok koca lamkah mah khosoih la hoep saeh. Te rhoek long tah ka kueknah a ngaithuen uh tih Levi kah khohmang bangla Israel ca loh kho a hmang akhaw te rhoek loh kho a hmang uh moenih.
Èyí yóò wà fún àwọn àlùfáà tí a yà sí mímọ́, àwọn ọmọ Sadoku tí wọn jẹ́ olóòtítọ́ nínú sí sìn mí, tiwọn kò sì ṣáko lọ bí ti àwọn Lefi ṣe ṣe nígbà tí àwọn Israẹli ṣáko lọ.
12 Te dongah Levi khorhi taengkah a cim la aka cim koek khohmuen kah khosaa te amih ham rhungkung buh la om saeh.
Èyí yóò jẹ́ ọrẹ pàtàkì fún wọn láti ara ìpín ibi mímọ́ ilẹ̀ náà, ìpín tí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ, tí ó jẹ́ ààlà agbègbè àwọn Lefi.
13 Levi kah khaw khosoih khorhi voeivang ah thawng kul thawng nga te a yun vetih a daang te thawng rha lo ni. A yun boeih te thawng kul thawng nga vetih a daang te thawng rha lo ni.
“Ní àkọjúsí agbègbè àwọn àlùfáà, àwọn Lefi yóò pín ìpín kan tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ ní ìbú. Gígùn rẹ̀ ní àpapọ̀ yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́, àti inú rẹ̀ yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́.
14 Te te yoi uh boel saeh lamtah tho boel saeh. Khohmuen tanglue he BOEIPA ham a cim dongah khum rhoe khum boel saeh.
Wọn kò gbọdọ̀ tà tàbí pààrọ̀ ọ̀kankan nínú rẹ̀. Èyí yìí ni ó dára jùlọ lára ilẹ̀ náà, a kò sì gbọdọ̀ fi fún ẹlòmíràn nítorí pé ó jẹ́ mímọ́ fún Olúwa.
15 A daang thawng kul thawng nga hmai la thawng nga aka hoei te khopuei ham neh tolrhum ham khaw khocaak ham khaw hmangrhong la om saeh. Tedae a laklo a laklo ah kho om saeh.
“Agbègbè tí o ṣẹ́kù, tí ń ṣe ẹgbẹ̀rún márùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú àti ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn, yóò jẹ́ ibi àìmọ́ fun ìlú ńlá náà fún ilé gbígbé àti fún agbègbè. Ìlú ńlá náà yóò wà ní àárín rẹ̀,
16 A cungnueh te tlangpuei saa dongah thawng li ya nga neh tuithim saa thawng li ya nga panga, khothoeng saa dongah thawng li ya nga neh khotlak saa dongah ah thawng li ya nga lo saeh.
ìwọ̀nyí sì níbi a ṣe wọ́n ọ́n: ní ìhà àríwá ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́, ni ìhà gúúsù ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́, ní ìhà ìlà-oòrùn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ àti ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́.
17 Khopuei kah khocaak ham te tlangpuei ah yahnih sawmnga, tuithim ah yahnih sawmnga, khothoeng ah yahnih sawmnga, khotlak ah yahnih sawmnga lo saeh.
Ilẹ̀ ìjẹ fún àwọn ẹran ọ̀sìn fún ìlú ńlá náà yóò jẹ igba àti àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ní ìhà gúúsù, ìgbà àti ìgbà pẹ̀lú àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ ní ìhà ìwọ̀-oòrùn.
18 Hmuencim khosa rhi kah a yun te khothoeng ah thawng rha, khotlak ah thawng rha coih pueng tih hmuencim khosaa voeivang ah om saeh. A vueithaih tah khopuei ah aka thotat kah a caak ham a vueithaih la om saeh.
Èyí tí ó kù ní agbègbè náà, tí ó jẹ́ àkọjúsí ìpín ibi mímọ́, gígùn rẹ̀ yóò sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ ni ìhà ìlà-oòrùn àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ìgbọ̀nwọ́ ní ìhà ìwọ̀-oòrùn. Ìpèsè rẹ̀ yóò fi kún oúnjẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ ìlú ńlá náà.
19 Khopuei kah aka thotat Israel koca boeih loh te te tawn saeh.
Àwọn òṣìṣẹ́ láti ìlú ńlá náà, tí ó ń dá oko níbẹ̀ yóò wá láti gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli.
20 Khosaa boeih te thawng kul thawng nga, thawng kul thawng nga ah pali la hmoel lamtah khopuei kah khohut neh hmuencim khosaa la om saeh.
Gbogbo ìpín náà yóò rí bákan náà ní ẹ̀gbẹ́ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin, èyí yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan. Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn pàtàkì ìwọ yóò fi ìpín ibi mímọ́ sí ẹ̀gbẹ́ kan, papọ̀ mọ́ ohun ìní ìlú ńlá náà.
21 Hmuencim khosaa neh khopuei kah khohut te heben ah khaw keben ah khaw khoboei ham sueng pah saeh. Khosaa te a hmai thawng kul thawng nga lamloh khothoeng khorhi hil pha saeh. Te phoeiah tuipuei hmai lamloh khotlak rhi thawng kul thawng nga hil voeivang phai te khoboei kah khoyo la om saeh. Te dongah khosaa hmuencim neh a im kah rhokso tah a laklung, a laklung ah om saeh.
“Èyí tí ó ṣẹ́kù ni ẹ̀gbẹ́ méjèèjì agbègbè tí ó jẹ́ ìpín ibi mímọ́ àti ohun ìní ìlú ńlá náà yóò jẹ́ ti àwọn ọmọ-aládé. Èyí yóò lọ títí dé ìhà ìlà-oòrùn láti ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ti ìpín ibi mímọ́ títí dé ààlà ìlà-oòrùn. Agbègbè méjèèjì wọ̀nyí ni gígùn àwọn ìpín ẹlẹ́yàmẹ́yà yóò jẹ́ ti àwọn ọmọ-aládé, àti ìpín ibi mímọ́ pẹ̀lú tẹmpili yóò wa ní àárín wọn.
22 Te dongah Levi khohut lamkah neh khopuei khohut lamkah a laklung te khoboei ham om pah saeh. Judah khorhi laklo neh Benjamin khorhi laklo te khoboei ham om pah saeh.
Ilẹ̀ ìní àwọn Lefi àti ohun ìní ìlú ńlá náà yóò wà ni àárín agbègbè tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ-aládé. Agbègbè tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ-aládé yóò wà ní àárín ààlà tí Juda àti ààlà tí Benjamini.
23 Te vaengah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te Benjamin koca kah hlangrhuel ham pakhat la om saeh.
“Ní ti àwọn ẹ̀yà tí ó kù: “Benjamini yóò ní ìpín kan; èyí yóò wà láti ìhà ìlà-oòrùn títí dé ìhà ìwọ̀-oòrùn.
24 Benjamin khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te Simeon ham pakhat om saeh.
Simeoni yóò ní ìpín kan: èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Benjamini láti ìlà-oòrùn lọ sí ìwọ̀-oòrùn.
25 Simeon khorhi phoeiah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te Issakhar ham pakhat om saeh.
Isakari yóò ní ìpín kan: èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Simeoni láti ìlà-oòrùn sí ìwọ̀-oòrùn.
26 Issakhar khorhi phoeikah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te Zebulun ham pakhat om saeh.
Sebuluni yóò ní ìpín kan; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Isakari láti ìlà-oòrùn sí ìwọ̀-oòrùn.
27 Zebulun khorhi phoeikah khothoeng baengki lamloh khotlak baengki hil te Gad ham pakhat om saeh.
Gadi yóò ní ìpín; èyí yóò jẹ́ ààlà agbègbè Sebuluni láti ìlà-oòrùn sí ìwọ̀-oòrùn.
28 Gad khorhi phoeikah tuithim khorhi te tah tuithim la yong. Te phoeiah khorhi te Kadesh soklong kah Meribah tui taeng Tamar lamloh tuipuei tanglue la pawk.
Ààlà tí gúúsù Gadi yóò dé gúúsù láti Tamari lọ sí odò Meriba Kadeṣi lẹ́yìn náà títí dé odo ti Ejibiti lọ sí Òkun ńlá.
29 Khohmuen he he Israel koca ham neh amamih boelnah bangla rho la naan pah. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni.
“Èyí ni ilẹ̀ tí ẹ̀yin yóò fi ìbò pín ní ogún fún àwọn ẹ̀yà Israẹli, wọ̀nyí sì ni ìpín wọn,” ní Olúwa Olódùmarè wí.
30 Khopuei a bawtnah rhoek he tlangpuei saa ah cungnueh thawng li ya nga lo saeh.
“Ìwọ̀nyí ní yóò jẹ́ ẹnu-ọ̀nà àbájáde ìlú ńlá náà: “Bẹ̀rẹ̀ láti ìhà àríwá, ti ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lè ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn,
31 Khopuei vongka rhoek te Israel koca ming la om vetih tlangpuei kah vongka pathum dongah Reuben vongka pakhat, Judah vongka pakhat, Levi vongka pakhat saeh.
ẹnu-ọ̀nà ìlú ńlá náà ní àwa yóò fi orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli pè. Àwọn ọ̀nà mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ní ìhà àríwá ní yóò jẹ́ ọ̀nà tí Reubeni, ọ̀nà tí Juda ọ̀nà tí Lefi.
32 Khothoeng saa dongkah te thawng li ya nga lo tih, vongka pathum dongah Joseph vongka pakhat, Benjamin vongka pakhat, Daan vongka pakhat saeh.
Ní ìhà ìlà-oòrùn, èyí tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn, ni ojú ọ̀nà mẹ́ta yóò wà: ọ̀nà Josẹfu, ọ̀nà tí Benjamini àti ọ̀nà tí Dani.
33 Tuithim saa khaw cungnueh ah thawng li ya nga lo. Vongka pathum dongkah te Simeon vongka pakhat, Issakhar vongka pakhat, Zebulun vongka pakhat saeh.
Ní ìhà gúúsù, èyí tí wíwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lè ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ ní ojú ọ̀nà mẹ́ta yóò wà: ojú ọ̀nà Simeoni, ojú ọ̀nà Isakari àti ojú ọ̀nà Sebuluni.
34 Khotlak saa ah thawng li ya nga lo bal. A vongka pathum dongah Gad vongka pakhat, Asher vongka pakhat, Naphtali vongka pakhat saeh.
Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn, èyí tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn, ní ojú ọ̀nà mẹ́ta yóò wà: ojú ọ̀nà Gadi, ojú ọ̀nà Aṣeri àti ojú ọ̀nà Naftali.
35 A kaepvai te thawng hlai rhet lo tih BOEIPA kah khohnin lamlong tah khopuei ming khaw pahoi om saeh.
“Jíjìnnà rẹ̀ yípo yóò jẹ́ ẹgbàá mẹ́sàn ìgbọ̀nwọ́. “Orúkọ ìlú náà láti ìgbà náà yóò jẹ́: ‘Olúwa wà níbẹ̀.’”

< Ezekiel 48 >