< Jeremiah 31 >

1 Te vaengkah a tue ah BOEIPA kah olphong om coeng. Israel cako boeih kah Pathen la ka om vetih amih te kamah taengah pilnam la om uh ni.
“Nígbà náà, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run fún gbogbo ìdílé ìran Israẹli, àwọn náà yóò sì jẹ́ ènìyàn mi,” ni Olúwa wí.
2 BOEIPA loh he ni a. thui. Cunghang kah a caknoi pilnam tah khosoek ah mikdaithen la a hmuh vetih Israel amah te hoep ham ni a. pongpa eh.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Àwọn ènìyàn tí ó sá àsálà lọ́wọ́ idà yóò rí ojúrere Olúwa ní aṣálẹ̀, Èmi yóò sì fi ìsinmi fún Israẹli.”
3 BOEIPA tah kai taengah daengrhae daengkhoi la ha phoe coeng dongah kumhal kah lungnah neh nang kan lungnah tih sitlohnah neh nang kan dangrhoek tangloeng coeng.
Olúwa ti fi ara rẹ̀ hàn wá ní ìgbà kan rí, ó wí pé: “Èmi ti nífẹ̀ẹ́ yín pẹ̀lú ìfẹ́ àìlópin; mo ti fi ìfẹ́ ńlá fà yín,
4 Israel oila nang te koep kan thoh vetih na thoo bitni. Na kamrhing te koep na oi vetih lamnah dongah na luem doela na pawk bitni.
Èmi yóò tún gbé e yín sókè, àní a ó tún gbé e yín ró ìwọ wúńdíá ilẹ̀ Israẹli. Àní ẹ ó tún tún ohun èlò orin yín gbé, ẹ ó sì jáde síta pẹ̀lú ijó àti ayọ̀.
5 Samaria tlang ah misur koep na phung te a phung, a phung uh vetih a poek a yak uh ni.
Ẹ ó tún gbin ọgbà àjàrà ní orí òkè Samaria; àwọn àgbẹ̀ yóò sì máa gbádùn èso oko wọn.
6 Ephraim tlang kah aka dawn rhoek loh, “Thoo uh lamtah mamih kah Pathen BOEIPA taengah Zion la cet uh sih,” tila a hoe uh khohnin khaw om bitni.
Ọjọ́ kan máa wà tí àwọn olùṣọ́ yóò kígbe jáde lórí òkè Efraimu wí pé, ‘Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a gòkè lọ sí Sioni, ní ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa.’”
7 BOEIPA loh he ni a. thui. Jakob ham tamhoe uh lamtah kohoenah neh hlampan uh. Namtom boeilu te yaak sak lamtah a thangthen neh, “BOEIPA aw na pilnam Israel kah a meet te khang laeh,” ti saeh.
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ wí pé: “Ẹ fi ayọ̀ kọrin sí Jakọbu; ẹ hó sí olórí àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo. Jẹ́ kí wọ́n gbọ́ ìyìn rẹ kí o sì wí pé, ‘Olúwa, gba àwọn ènìyàn rẹ là; àwọn tí ó ṣẹ́kù ní Israẹli.’
8 Amih te tlangpuei khohmuen lamloh kang khuen coeng he. Te dongah amih te diklai a hlaep lamloh ka coi ni. Amih taengkah mikdael neh khokhaem khaw, aka vawn neh cacun khaw hlangping la muep ha mael uh rhenten ni.
Wò ó, Èmi yóò mú wọn wá láti ilẹ̀ àríwá; èmi yóò kó gbogbo wọn jọ láti òpin ayé. Lára wọn ni yóò jẹ́ afọ́jú àti arọ, aboyún àti obìnrin tí ń rọbí, ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò wá.
9 Rhahnah neh ha pawk uh cakhaw amih huithuinah neh ka khuen ni. Amih te soklong tui ah ka pongpa puei vetih, a thuem longpuei ah paloe uh mahpawh. Israel taengah ana pa la ka om tih Ephriam te ka caming ni.
Wọn yóò wá pẹ̀lú ẹkún, wọn yóò gbàdúrà bí Èmi yóò ṣe mú wọn padà. Èmi yóò jẹ́ atọ́nà fún wọn ní ẹ̀bá odò omi; ní ọ̀nà tí ó tẹ́jú tí wọn kì yóò le ṣubú, nítorí èmi ni baba Israẹli, Efraimu sì ni àkọ́bí ọkùnrin mi.
10 Namtom rhoek BOEIPA ol he hnatun uh. Khohla bangsang kah sanglak ah khaw puen uh lamtah Israel khuikah a thaekyak te thui pah. Anih te a coi vetih a tuping aka dawn bangla anih te a ngaithuen ni.
“Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin orílẹ̀-èdè ẹ kéde rẹ̀ ní erékùṣù jíjìn; ‘Ẹni tí ó bá tú Israẹli ká yóò kójọ, yóò sì ṣọ́ agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn.’
11 BOEIPA loh Jakob te a lat tih anih lakah tlungluen kut lamloh a tlan coeng.
Nítorí Olúwa ti tú Jakọbu sílẹ̀, o sì rà á padà ní ọwọ́ àwọn tí ó lágbára jù ú lọ.
12 Ha pawk uh vaengah Zion hmuensang ah tamhoe uh ni. BOEIPA kah thennah dongah, cangpai dongah, misur thai dongah, situi dongah, boiva neh saelhung ca dongah hlampan uh ni. A hingah te khosul dum bangla om vetih a kha koep ham koei mahpawh.
Wọn yóò wá, wọn ó sì hó ìhó ayọ̀ lórí òkè Sioni; wọn yóò yọ ayọ̀ níbi oore Olúwa. Àlìkámà ni, ọtí wáìnì tuntun àti òróró ọ̀dọ́-àgùntàn àti ọ̀dọ́ ọ̀wọ́ ẹran. Wọn ó dàbí ọgbà àjàrà tí a bomirin, ìkorò kò ní bá wọn mọ́.
13 Te vaengah oila khaw tongpang neh patong taengah lamnah neh thikat la a kohoe ni. Amih kah nguekcoinah te omngaihnah la ka hoi pah vetih amih te ka hloep ni. Amih kah kothaenah yueng la amih ko ka hoe sak ni.
Àwọn wúńdíá yóò jó, wọn ó sì kún fún ayọ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọkùnrin àti obìnrin. Èmi yóò sọ ọ̀fọ̀ wọn di ayọ̀, dípò ìkorò èmi yóò tù wọ́n nínú. Èmi ó sì fún wọn ní ayọ̀.
14 Khosoih rhoek kah hinglu te maehhloi neh ka sulpuem sak vetih ka pilnam khaw ka thennah neh cung uh ni. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Èmi ó tẹ́ àwọn àlùfáà lọ́rùn pẹ̀lú ọ̀pọ̀; àwọn ènìyàn mi yóò sì kún fún oore mi,” ni Olúwa wí.
15 BOEIPA loh he ni a. thui. Ramah ah rhathinah ol a yaak. Rakhel tah a ca rhoek ham kosidung kah rhahnah neh rhap coeng. A ca rhoek a om pawt dongah kohlawt ham khaw a aal coeng.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “A gbọ́ ohùn kan ní Rama tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò. Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀; kò gbà kí wọ́n tu òun nínú, nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”
16 BOEIPA loh he ni a. thui. Na ol te rhahnah lamloh, na mik te khaw mikphi lamloh tuem laeh. BOEIPA kah olphong bangla na khoboe ham thapang om vetih thunkha khohmuen lamloh ha mael uh bitni.
Báyìí ni Olúwa wí: “Dá ohùn rẹ dúró nínú ẹkún àti ojú rẹ nínú omijé; nítorí a ó fi èrè sí iṣẹ́ rẹ,” ni Olúwa wí. “Wọn ó sì padà wá láti ilẹ̀ ọ̀tá.
17 BOEIPA kah olphong bangla na hmailong ham ngaiuepnah om tangloeng coeng tih ca rhoek khaw a khorhi la mael uh bitni.
Nítorí ìrètí wà fún ọjọ́ iwájú rẹ,” ni Olúwa wí. “Àwọn ọmọ rẹ yóò padà wá sí ilẹ̀ wọn.
18 Ephraim kah a rhaehba te a yaak rhoela ka yaak coeng. Kai nan thuituen vaengah a phaep noek pawh vaitoca bangla n'thuituen coeng. Namah tah BOEIPA ka Pathen la na om dongah kai m'mael sak lamtah ka mael pawn eh.
“Nítòótọ́, èmi ti gbọ́ ìpohùnréré Efraimu wí pé, ‘Ìwọ ti bá mi wí gẹ́gẹ́ bí ọmọ màlúù tí a kò kọ́ èmi sì ti gbọ́ ìbáwí. Rà mí padà, èmi yóò sì yípadà, nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run mi.
19 Ka mael hnukah ni damti coeng. Ka hlit dongkah kutpaeng khaw ka ming phoeiah ni ka yah pueng. Ka camoe lamkah kokhahnah te ka phueih tih ka hmaithae coeng.
Lẹ́yìn tí èmi ti yípadà, mo ronúpìwàdà, lẹ́yìn tí èmi ti wá mọ̀, èmi lu àyà mi. Ojú tì mí, mo sì dààmú; nítorí èmi gba èrè ẹ̀gàn ìgbà èwe mi.’
20 Ephraim he kamah taengkah oingaih capa maco? Anih te ka thui dingdoeng vaengah khaw hlahmaenah camoe ni. Te dongah anih te ka poek rhoe ka poek pueng. Ka ko anih hamla umya tih anih te haidam rhoela ka haidam coeng. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Efraimu kì í ha í ṣe ọmọkùnrin mi dáradára tí inú mi dùn sí bí? Bí èmi ti ń sọ̀rọ̀ sí i tó, síbẹ̀, èmi rántí rẹ̀. Nítorí náà, ọkàn mi ṣe ohun kan fún un, èmi káàánú gidigidi fún un,” ni Olúwa wí.
21 Namah ham pangkae te ling lamtah miknawt khaw namah ham khueh laeh. Longpuei lamhlawn te na lungbuei ah dueh lamtah pongpa rhoe pongpa laeh. Israel oila ha mael lamtah na khopuei ah he ha mael laeh.
“Gbé àmì ojú ọ̀nà dìde, ṣe atọ́nà àmì, kíyèsi òpópó ọ̀nà geere ojú ọ̀nà tí ó ń gbà. Yípadà ìwọ wúńdíá Israẹli, padà sí àwọn ìlú rẹ.
22 Hnukmael canu te me hil nim na dongpam ve? BOEIPA loh diklai dongah a thai la a suen vetih huta tongpa loh a vael bitni.
Ìwọ yóò ti ṣìnà pẹ́ tó, ìwọ aláìṣòótọ́ ọmọbìnrin; Olúwa yóò dá ohun tuntun lórí ilẹ̀, ọmọbìnrin kan yóò yí ọkùnrin kan ká.”
23 Israel Pathen caempuei BOEIPA loh he ni a. thui. He ol he Judah kho khui neh a khopuei rhoek khuiah koep a thui uh vaengah amih khuikah thongtla te kai taengla ha mael ni. Duengnah tlang cim tolkhoeng dongkah BOEIPA loh nang n'uem nawn saeh.
Báyìí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Israẹli wí: “Nígbà tí èmi bá kó wọn dé láti ìgbèkùn; àwọn ènìyàn tí ó wà ní ilẹ̀ Juda àti ní àwọn ìlú rẹ̀ yóò tún lo àwọn ọ̀rọ̀ yìí lẹ́ẹ̀kan sí i; wí pé, ‘Kí Olúwa kí ó bùkún fún ọ, ìwọ ibùgbé òdodo, ìwọ òkè ìwà mímọ́.’
24 Te vaengah Judah amah neh a khopuei boeih ah tun kho a sak uh lopho khaw tuping neh ha hlah uh ni.
Àwọn ènìyàn yóò gbé papọ̀ ní Juda àti ní gbogbo àwọn ìlú rẹ̀; bákan náà ni àgbẹ̀ àti àwọn tí ń tẹ̀lé agbo ẹran wọn ká.
25 Buhmueh rhathih kah a hinglu te ka sulpuem sak vetih aka kha kah hinglu te boeih ka cung sak ni.
Èmi yóò sọ aláàárẹ̀ di ọ̀tun, èmi yóò sì tẹ́ gbogbo ọkàn tí ń káàánú lọ́rùn.”
26 Ka haenghang vaengah he khaw ka sawt tih ka ih khaw kai ham tui mai.
Lórí èyí ni mo jí, mo sì wò yíká, oorun mi sì dùn mọ́ mi.
27 BOEIPA kah olphong khohnin ha pawk coeng ke. Israel imkhui neh Judah imkhui khaw, hlang kah tiingan neh rhamsa kah tiingan khaw ka phul pueng ni.
“Wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “nígbà tí èmi yóò gbin ilé Israẹli àti ilé Juda pẹ̀lú irúgbìn ọmọ ènìyàn àti ẹranko.
28 Phuk ham neh phil ham khaw, koengloeng ham neh milh sak ham khaw, thaehuet ham khaw amih ka hak thil bangla thoeng van. Te dongah thoh ham neh phung ham khaw amih te ka hak thil ni. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ń ṣọ́ wọn, láti fàtu, àti láti wó lulẹ̀, àti láti gba ìṣàkóso, láti bàjẹ́ àti láti mú ibi wá, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣọ́ wọn láti kọ́ àti láti gbìn,” ni Olúwa wí.
29 Te khohnin ah tah, “A napa rhoek loh thaihkang a caak uh tih a ca rhoek a no yaa,” ti uh voel mahpawh.
“Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ènìyàn kò ní sọ mọ́ pé: “‘Àwọn baba ti jẹ èso àjàrà àìpọ́n àti pé eyín kan àwọn ọmọdé.’
30 Tedae hlang he amah kathaesainah dongah ni a. duek eh. Thaihkang aka ca hlang boeih tah a no yaa ni.
Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ni yóò kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ èso kíkan ni eyín yóò kan.
31 BOEIPA kah olphong khohnin tah ha pawk coeng ke. Israel imkhui taeng neh Judah imkhui taengah paipi thai ka saii ni.
“Ìgbà kan ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò bá ilé Israẹli àti ilé Juda dá májẹ̀mú tuntun.
32 Egypt kho lamloh amih khuen ham a kut ah ka talong khohnin vaengkah a napa rhoek neh ka saii paipi bang te moenih. Amih loh ka paipi he phae cakhaw kai amih te ka yuunah ngawn ta. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Kò ní dàbí májẹ̀mú tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá, nígbà tí mo fà wọ́n lọ́wọ́, tí mo mú wọn jáde ní Ejibiti nítorí wọ́n da májẹ̀mú mi. Lóòótọ́ ọkọ ni èmi jẹ́ fún wọn,” ni Olúwa wí.
33 Tedae paipi he Israel imkhui neh ka saii phoeikah khohnin ah tah ka olkhueng he amih kotak khuiah ka paek vetih a lungbuei ah ka daek pah ni. He tah BOEIPA kah olphong ni. Amih taengah Pathen la ka om vetih amih khaw kamah taengah pilnam la om uh ni.
“Èyí ni májẹ̀mú tí èmi yóò bá ilé Israẹli dá lẹ́yìn ìgbà náà,” ni Olúwa wí pé: “Èmi yóò fi òfin mi sí ọkàn wọn, èmi ó sì kọ ọ́ sí àyà wọn. Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn; àwọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi.
34 Hlang loh a hui te koep tukkil uh pawt vetih hlang loh a manuca te, “BOEIPA te ming laeh,” ti nah mahpawh. Amih te tanoe lamloh kangham duela kai boeih m'ming uh ni. He tah BOEIPA kah olphong ni. Amih kathaesainah te khodawk ka ngai vetih a tholhnah te ka poek voel mahpawh.
Kò ní sí pé ọkùnrin kan ń kọ́ àwọn ará ilé rẹ̀ tàbí ọkùnrin ń kọ́ arákùnrin rẹ̀ pé, ‘Ẹ mọ Olúwa,’ nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀ mí láti ẹni kékeré wọn títí dé ẹni ńlá,” ni Olúwa wí. “Nítorí èmi ó dárí àìṣedéédéé wọn jì, èmi kò sì ní rántí ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.”
35 BOEIPA loh he ni a. thui. Khothaih kah vangnah ham khomik, khoyin kah vangnah ham hla neh aisi kah khosing khaw a khueh. Tuitunli te a kueng tih a tuiphu khaw kawk coeng. A ming tah caempuei BOEIPA ni.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ẹni tí ó mú oòrùn tan ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀sán, tí ó mú òṣùpá àti ìràwọ̀ ràn ní òru; tí ó rú omi Òkun sókè tó bẹ́ẹ̀ tí ìjì rẹ̀ fi ń hó Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
36 He tah BOEIPA kah olphong ni. Oltlueh he ka mikhmuh lamloh khum koinih hnin takuem ka mikhmuh ah namtu la aka om Israel tiingan khaw kangkuen uh ni.
“Àyàfi tí ìlànà yìí bá kúrò níwájú mi,” ni Olúwa wí. “Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Israẹli yóò dẹ́kun láti jẹ́ orílẹ̀-èdè níwájú mi láéláé.”
37 BOEIPA loh he ni a. thui. Vaan ke a so la a nueh uh thai tih diklai a yung hmui duela a khe uh thai mak atah Israel kah tiingan boeih te a saii cungkuem dongah ka hnawt van bitni. He tah BOEIPA kah olphong ni.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Àyàfi tí a bá lé àwọn ọ̀run lókè tí ìpìlẹ̀ ayé sì di àwárí ní ìsàlẹ̀, ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli nítorí ohun gbogbo tí wọ́n ti ṣe,” ni Olúwa wí.
38 BOEIPA kah olphong khohnin ha pawk coeng ke. Te vaengah bangkil vongka kah Hananel rhaltoengim lamloh BOEIPA ham khopuei a thoh ni.
“Ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí wọn yóò tún ìlú yìí kọ́ fún mi láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé igun ẹnu ibodè.
39 Gareb som te a hmai la rhilam rhui sen a toe thil vetih Goah duela a vael ni.
Okùn ìwọ̀n yóò sì nà jáde láti ibi gígùn lọ sí òkè Garebu yóò sì lọ sí Goa.
40 Rhok neh maehhloi aka om tuikol boeih, lohmali neh hmangrhong boeih khaw, Kidron soklong neh khothoeng kah marhang vongka bangkil duela BOEIPA ham hmuencim la om ni. Kumhal duela koep kuel pawt vetih koengloeng voel mahpawh.
Gbogbo àfonífojì níbi tí wọ́n ń da òkú àti eérú sí, àti gbogbo àfonífojì Kidironi ní ìhà ìlà-oòrùn títí dé igun ẹnu ibodè ẹṣin yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa. A kì yóò fa ìlú náà tu tàbí kí a wó o palẹ̀.”

< Jeremiah 31 >