< Jeremiah 24 >

1 Babylon manghai Nebukhanezar loh Judah manghai Jehoiakim capa Jekoniah neh Judah mangpa rhoek te a poelyoe tih Jerusalem lamkah kutthai neh thidae te Babylon la a khuen phoeiah BOEIPA bawkim hmai kah voh rhoi dongah thaibu thaih a khueh te BOEIPA loh kai tarha n'tueng.
Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
2 Voh khat dongkah thaibu thaih tah thaibu thaihloe bangla bahoeng then. Voh pakhat dongkah thaibu thaih tah a thaenah khui lamloh caak pawt ham hil bahoeng thae.
Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
3 Te vaengah BOEIPA loh kai taengah, “Jeremiah balae na hmuh,” a ti. Te dongah, “Thaibu thaibu rhoe mah aka then tah bahoeng then tih aka thae tah a thae uet ah a thaenah lamloh caak la lo pawh,” ka ti tah.
Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
4 Te vaengah BOEIPA ol tah kai taengah ha pawk tih,
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
5 “He tah Israel Pathen BOEIPA long ni a thui. He kah thaibu then bangla Judah hlangsol te ka hmat van. Te khaw he hmuen lamloh Khalden khohmuen ah a then lam ni ka tueih.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
6 Ka mik he amih soah a then la ka khueh vetih amih te he khohmuen la ka mael sak ni. Amih te ka thoh vetih ka koengloeng mahpawh. Amih te ka phung vetih ka phuk mahpawh.
Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
7 Kai kamah he BOEIPA ni tila ming sak ham lungbuei te amih taengah ka paek ni. Te vaengah kamah kah pilnam la om uh vetih kai khaw amih kah Pathen la ka om van ni. A lungbuei boeih neh kai taengla ha mael uh mak atah,” a ti.
Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
8 Tedae thaibu aka thae bangla a thaenah lamloh a caak thai pawt te BOEIPA loh, “Judah manghai Zedekiah neh a mangpa rhoek taengah khaw, he khohmuen ah aka sueng Jerusalem kah a meet rhoek taengah khaw, Egypt kho kah khosa rhoek taengah khaw ka khueh van ni.
“‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
9 Amih te tonganah neh ngaihuetnah la, yoethaenah la ka khueh vetih diklai ram tom taengah kokhahnah la, thuidoeknah la thuinuetnah la, rhunkhuennah la ka khueh vetih amih te hmuen takuem ah te ka heh ni.
Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
10 Amamih taeng neh a napa rhoek taengah ka paek khohmuen dong lamloh a cing uh duela amih taengah cunghang, khokha neh duektahaw te ka tueih pah ni.
Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”

< Jeremiah 24 >