< Nambar 30 >
1 Angraeng mah thuih ih lok to Mosi mah Israel zaehoikungnawk khaeah hae tiah thuih pae.
Mose sì sọ fún olórí àwọn ẹ̀yà ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ,
2 Kami maeto mah Angraeng khaeah lokkamhaih a sak, to tih ai boeh loe palung thung hoiah hmuen maeto sak han thui nahaeloe, a thuih ih lok to amkhrai han om ai;
nígbà tí ọkùnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀ ní ìdè kí òun má bà ba ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ.
3 nongpata maeto loe nawkta vop, ampa im ah oh nathuem ah, Angraeng khaeah lokkamhaih sak moe, a poekhaih baktiah hmuen maeto sak hanah amsak;
“Nígbà tí ọmọbìnrin kan bá sì wà ní ilé baba rẹ̀ tó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀
4 anih ih lokkamhaih hoiah sak han atim ih lok to ampa mah kawbangah doeh naa ai, omtaak duem nahaeloe, hmuen maeto sak han lokkamhaih hoiah a thuih ih lok to cak tih boeh.
tí baba rẹ̀ bá sì gbọ́ ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí ìdè rẹ̀ tí kò sì sọ nǹkan kan sí i, kí gbogbo ẹ̀jẹ́ rẹ̀ kí ó dúró àti gbogbo ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ yóò sì dúró.
5 Toe anih lokkamhaih to ampa mah kaang pae khruek nahaeloe, sak han lokkamhaih to cak mak ai; ampa mah kaang pongah, Angraeng mah anih to tahmen tih.
Ṣùgbọ́n tí baba rẹ̀ bá kọ̀ fun un ní ọjọ́ tí ó gbọ́, kò sí ọ̀kan nínú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí nínú ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tí yóò dúró; Olúwa yóò sì tú u sílẹ̀ nítorí baba rẹ̀ kọ̀ fún un.
6 Nongpata loe sava tawnh moe, a lokkamhaih baktiah maw, to tih ai boeh loe hmuen maeto ka sak han, tiah pahni hoiah thuih naah,
“Tí ó bá sì ní ọkọ lẹ́yìn ìgbà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí lẹ́yìn ìgbà tí ó sọ ọ̀rọ̀ kan láti ẹnu rẹ̀ jáde nínú èyí tí ó fi de ara rẹ̀ ní ìdè,
7 a sava mah thaih, toe a thaih niah kawbangah doeh naa ai, omtaak duem nahaeloe, a sak ih lokkamhaih hoi a thuih ih lok to caksak han oh.
tí ọkọ rẹ̀ sì gbọ́ nípa èyí ṣùgbọ́n tí kò sọ nǹkan kan, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tó dúró.
8 Toe a sava mah thaih na niah sak han ai ah pakaa pae khruek nahaeloe, anih lokkamhaih maw, pahni hoiah thuih ih lok maw loe azom ah ni om tih; Angraeng mah doeh anih to tahmen tih.
Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá kọ̀ nígbà tí ó gbọ́, ǹjẹ́ òun yóò mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tí ó jẹ́ àti ohun tí ó ti ti ẹnu rẹ̀ jáde, èyí tí ó fi de ara rẹ̀ dasán, Olúwa yóò sì dáríjì í.
9 Lamhmaih nongpata hoi sava mah pakhrak ih nongpata mah lokkamhaih sah nahaeloe, a lokkamhaih to caksak han oh.
“Ṣùgbọ́n ẹ̀jẹ́ kí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè kí ìdè tí opó tàbí obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ bá ṣe yóò wà lórí rẹ̀.
10 Sava tawn nongpata mah lokkamhaih to sak han ih maw, to tih ai boeh loe hmuen maeto sak han lokkamhaih sak naah,
“Bí obìnrin tí ó ń gbé pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí de ara rẹ̀ ní ìdè lábẹ́ ìbúra,
11 a sava mah thaih, toe pakaa ai, kawbangah doeh naa ai, omtaak duem nahaeloe, hmuen maeto sak han lokkamhaih hoiah a thuih ih lok to cak tih.
tí ọkọ rẹ̀ bá sì gbọ́, ṣùgbọ́n tí kò sọ̀rọ̀, tí kò sì kọ̀, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ rẹ̀ yóò dúró.
12 Toe sava mah to lok to thaih na niah a lok to aek pae nahaeloe, pahni hoiah thuih ih lokkamhaih hoiah sak han thuih ih lok to cak mak ai; a sava mah phraek boeh pongah, Angraeng mah doeh anih to tahmen tih.
Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá sọ wọ́n dasán, nígbà tí ó gbọ́, nígbà náà kò sí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde tí yóò dúró, ọkọ rẹ̀ ti sọ wọ́n dasán, Olúwa yóò tú u sílẹ̀.
13 A poekhaih amtang hanah a sak ih lokkamhaih boih, hmuen maeto sak han thuih ih lok boih loe, a sava mah caksak thaih baktiah, a phraek thaih.
Ọkọ rẹ̀ lè ṣe ìwádìí tàbí sọ ọ́ dasán ẹ̀jẹ́ tàbí ìbúra ìdè tí ó ti ṣe láti fi de ara rẹ̀.
14 Toe a sava mah to hmuen kawng pongah, nito pacoeng nito tidoeh thui ai ah omtaak duem nahaeloe, to nongpata mah lokkamhaih hoiah sak han thuih ih loknawk boih loe cak tih; a sava mah thaih, toe anih to kawbangah doeh naa ai pongah, a thuih ih lok to cak tih.
Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ kò bá sọ nǹkan kan sí í nípa rẹ̀ ní ọjọ́ dé ọjọ́, nígbà náà ni ó ṣe ìwádìí nípa ẹ̀jẹ́ àti ìbúra ìdè tí ó dè é. Kí ọkùnrin náà ṣe ìwádìí lórí rẹ̀ láìsọ nípa rẹ̀ si nígbà tí ó gbọ́ nípa rẹ̀.
15 Toe sava mah thaih pacoengah hnukkhuem ah phraek han thui nahaeloe, a zu zaehaih to sava nuiah krah tih, tiah a naa.
Bí ó ti wù kí ó rí, bí ọkùnrin náà bá sọ ọ́ dasán, ní àkókò kan lẹ́yìn tí ó ti gbọ́ wọn, nígbà náà ó jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà.”
16 Hae loe Angraeng mah Mosi khaeah thuih pae ih, zu sava salak, ampa hoi ampa im ah kaom a canu tangla salakah khosakhaih atawk ah oh.
Èyí ni ìlànà tí Olúwa fún Mose nípa ìbátan láàrín ọkùnrin àti obìnrin àti láàrín baba àti ọ̀dọ́mọbìnrin rẹ̀ tí ó sì ń gbé ní ilé rẹ̀.