< Nambar 15 >
1 Angraeng mah Mosi khaeah,
Olúwa sọ fún Mose pé,
2 Israel kaminawk khaeah hae tiah thui paeh; nihcae khaeah, Kang paek ih prae thungah na kun o naah,
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
3 Angraeng khaeah hmai angbawnhaih to sah oh; maitaw maw, to tih ai boeh loe tuu to Angraeng khaeah hmai angbawnhaih ah paek oh; maitaw doeh, tuu doeh Angraeng khaeah hmuihoih hmuen ah maw, to tih ai boeh loe angbawnhaih maw, to tiah ai boeh loe tathlang ih hmuen ah maw, to tih ai boeh loe lokkamhaih sak han ih maw, to tih ai boeh loe aimah koehah paek ih hmuen tathlanghaih maw, poihsakhaih ah tathlang ih hmuen ah maw sah oh:
tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
4 mi kawbaktih doeh Angraeng khaeah hmuen paekhaih sin kami loe, cang paekhaih sak naah situi hint palito thungah maeto hoi atok ih takaw dip ephah hato thungah maeto paek han oh;
nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
5 tuucaa hoi angbawnhaih sah nahaeloe, naek han koi hmuen hoi misurtui hint palito thungah maeto paek han oh.
Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
6 Tuu tae maeto hoi angbawnhaih sah nahaeloe, cang ephah hato thungah hnetto, situi hint thumto thungah hint maeto hoi atok ih takaw dip to paek han oh,
“‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
7 Angraeng khaeah hmuihoih ah hmuen tathlang nahaeloe, naek koi paek naah misurtui hint thumto thungah maeto paek han oh.
Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
8 Angraeng khaeah maitaw tae hoi angbawnhaih maw, to tih ai boeh loe hmuen paekhaih, to tih ai boeh loe lokkamhaih sak han angbawnhaih maw, to tih ai boeh loe angdaeh angbawnhaih maw sak naah,
“‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
9 maitaw tae hoi nawnto situi hint ahap hoi atok tangcae ih takaw dip ephah hato thungah thumto sin ah.
ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
10 Naek hanah misurtui hint ahap to sin ah. To tiah hmai hoi sak ih angbawnhaih loe Angraeng khaeah paek ih hmuihoih ah oh.
Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
11 Maitaw tae maeto, to tih ai boeh loe tuu tae maeto, to tih ai boeh loe tuucaa maeto, to tih ai boeh loe maeh caa maeto hoi angbawnhaih sak naah to tiah sak han oh.
Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
12 Kapop maw, tamsi maw, sak na timhaih nuiah pakoep ah loe, maeto boih hanah to tiah sah ah.
Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
13 Prae thung tapen kaminawk boih mah, Angraeng khaeah hmuihoih sin han hmai hoi angbawnhaih sak naah, to tiah sak han oh.
“‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
14 Nangcae salakah kaom angvinnawk maw, to tih ai boeh loe mi kawbaktih doeh, hmuihoih ah paek han Angraeng khaeah hmai hoi angbawnhaih sak naah, nangcae mah sak ih baktih toengah a sak o toeng han oh.
Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
15 Hing thung na caanawk mah pazui o poe hanah paek ih atawk loe, nangcae amkhueng kaminawk hoi nangcae salakah kaom angvinnawk hanah doeh maeto ah ni oh; nangcae Angraeng hmaa ah oh baktih toengah, angvin doeh om toeng tih.
Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
16 Nangcae hoi nangcae salakah kaom angvinnawk hanah, daan maeto hoi atawk maeto ah omsak ah, tiah a naa.
Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
17 Angraeng mah Mosi khaeah,
Olúwa sọ fún Mose pé,
18 Israel kaminawk khaeah hae tiah thui paeh; nihcae khaeah, Kang hoih o han ih prae thungah na kun o naah,
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
19 to prae thung ih takaw na caak o naah doeh, Angraeng khaeah hmuen tathlanghaih to sah oh.
Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
20 Na daengh tangsuek ih takaw dip hoi sak ih takaw hoi na tit tangsuek ih cang to paek ah.
Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
21 Na caanawk mah hmaloe koek daengh ih takaw to Angraeng khaeah paek o han oh.
Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
22 Angraeng mah Mosi khaeah paek ih lok na pazui o ai moe,
“‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
23 Angraeng mah Mosi patohhaih rang hoiah ang thuih ih lok to na pazui o ai nahaeloe, Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih ni hoi kamtong angzo han koi caanawk dung khoek to,
èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
24 amkhueng kaminawk mah panoek ai ah, poek ai pui hoi zaehaih sah moeng nahaeloe, rangpuinawk mah Angraeng khaeah hmuihoih angbawnhaih sak hanah, a sak o zong ih atawk baktih toengah, saning kanawk maitaw caa to cang hoi nawnto paek o ueloe, zae angbawnhaih sak hanah maeh caa to paek o tih.
Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
25 Qaima mah kaminawk boih hanah zae angbawnhaih to sah pae tih, to naah nihcae mah poek ai pui hoiah a sak o moeng ih zaehaih to tahmen pae tih; Angraeng khaeah hmai hoi angbawnhaih, poek ai pui hoi sak ih zae angbawnhaih sak hanah hmuen to sin o han oh.
Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
26 To tiah sah o nahaeloe, Israel kaminawk hoi nihcae salakah kaom angvinnawk boih mah, poek ai pui hoi sak o moeng ih zaehaih to loihsak tih.
A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
27 Toe kami maeto mah poek ai pui hoiah zaehaih sah moeng nahaeloe, zae angbawnhaih ah saningto kaom, maeh tala maeto a sin han oh.
“‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
28 Poek ai pui hoi Sithaw hmaa ah zaehaih sah kami hanah, qaima mah zae angbawnhaih to sah pae tih; to naah anih zaehaih to loisak tih.
Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
29 Poek ai pui hoi zaehaih sak o naah, Israel kami hoi nihcae salakah kaom angvin hanah doeh, daan maeto khue tawnh han oh.
Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
30 Toe prae thung tapen Israel kami maw, to tih ai boeh loe angvin maw, zithaih tawn ai ah zaehaih to sah nganga nahaeloe, Angraeng khingyahaih tawn ai pongah, to kami to acaeng thung hoiah pahnawt han oh.
“‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
31 Anih loe Angraeng ih lok to patoek moe, anih ih lok to aek pongah, to kami to pahnawt sut han oh; anih loe sakpazaehaih atho to hnu tih, tiah a naa.
Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
32 Israel kaminawk praezaek ah oh o naah, Sabbath niah thing aek kami maeto a hnuk o.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
33 Thing aek kami hnukungnawk mah anih to Mosi, Aaron hoi Israel kaminawk boih hmaa ah hoih o.
Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
34 Thing aek kami to kawbang maw lokcaek han tito amtueng ai vop pongah, anih to imthung ah paung o.
wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
35 To naah Angraeng mah Mosi khaeah, To kami loe duek han oh; anih to ataihaih tasa bangah kaminawk boih mah thlung hoiah va o mat tih, tiah a naa.
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
36 To pongah acaeng kaminawk mah anih to ataihaih imthung hoi tasa bangah zaeh o moe, Angraeng mah Mosi khaeah paek ih lok baktih toengah, duek khoek to thlung hoiah vah o.
Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
37 Angraeng mah Mosi khaeah,
Olúwa sọ fún Mose pé,
38 Israel kaminawk khaeah hae tiah thui paeh; angzo han koi caa nawktanawk khoek to, khukbuen atom nuiah rong kahing hoi bangh hanah, apawk to soi ah;
“Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
39 to apawknawk to na hnuk o naah, palung thung hoiah na poek o ih baktih toengah caeh moe, mik hoiah na hnuk o ih hmuen hnukah na patom pacoengah, na caeh o pazae han ai ah, Angraeng mah thuih ih loknawk to pakuem o poe ah loe sah oh;
Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
40 to naah kang paek o ih loknawk to pazui boih hanah na panoek o ueloe, na Sithaw khaeah ciimcai hanah kamhoe ah na om tih.
Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
41 Kai loe na Sithaw ah oh hanah, Izip prae thung hoi nangcae zaehoikung, na Angraeng Sithaw ah ka oh; Kai loe na Angraeng Sithaw ah ka oh tiah, a thuih, tiah thui paeh, tiah a naa.
Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”