< Exodus 4 >

1 Mosi mah, Toe, khenah, nihcae mah kai na tang o ai moe, ka lok tahngai ai ah, nang khaeah Angraeng angphong ai, tiah na naa o nahaeloe? tiah a naa.
Mose dáhùn ó sì wí pé, “Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá gbà mí gbọ́ ń kọ́? Tàbí tí wọn kò fi etí sílẹ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu mi, tí wọn sì wí pé, ‘Olúwa kò farahàn ọ́’?”
2 To naah Angraeng mah, anih khaeah, Na ban ah timaw na tawnh? tiah a naa. Anih mah, Cunghet, tiah pathim pae.
Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún un pé, “Kí ni ó wà ní ọwọ́ rẹ n nì?” Ó sì dáhùn pé, “Ọ̀pá ni.”
3 Angraeng mah, Long ah va tathuk ah, tiah a naa. Mosi mah cunghet to long ah vah tathuk naah, pahui ah angcoeng, to naah Mosi mah cawnhtak ving.
Olúwa sì sọ pé, “Sọ ọ̀pá náà sílẹ̀.” Mose sì sọ ọ̀pá náà sílẹ̀, lọ́gán ni ọ̀pá náà di ejò, ó sì sá fún un.
4 Angraeng mah, anih khaeah, Na ban to payangh loe, tamai ah naeh ah, tiah a naa. To pongah Mosi mah a ban to payangh moe, pahui to naeh, to naah a ban pongah cunghet ah angcoeng let.
Nígbà náà ni Olúwa wá sọ fún un pé, “Na ọwọ́ rẹ, kí o sì mú un ni ìrù.” Mose sì na ọwọ́ rẹ̀, ó sì mu ejò náà, ejò náà sì padà di ọ̀pá tí ó wà ni ọwọ́ rẹ̀.
5 Angraeng mah, To tiah na sak nahaeloe ampanawk ih Angraeng Sithaw, Abraham Sithaw, Isaak Sithaw, Jakob Sithaw loe nang khaeah angphong tangtang, tiah tanghaih tawn o tih, tiah a naa.
Olúwa sì wí pé, “Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí wọn bá à le è gbàgbọ́ pé, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu; tí farahàn ọ́.”
6 To pacoengah Angraeng mah, Vaihi laihaw thungah na ban to tapawh ah, tiah a naa. Mosi mah laihaw thungah a ban to tapawh; khenah, a ban azuh let naah, a ban loe dantui baktih kanglung, ngansae ah angcoeng.
Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, “Ti ọwọ́ rẹ bọ inú aṣọ ní igbá àyà rẹ̀.” Mose sì ti ọwọ́ rẹ̀ bọ inú aṣọ ní igbá àyà rẹ̀, ní ìgbà ti ó sì yọ ọ́ jáde, ọwọ́ rẹ̀ ti dẹ́tẹ̀, ó sì ti funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
7 Laihaw thungah na ban to tapawh let ah, tiah a naa. To pongah Mosi mah laihaw thungah a ban to tapawh let; a ban to lak let naah, khenah, a ban loe angmah ih ngan baktih toengah oh let.
Ó sì wí pé, “Nísinsin yìí, fi ọwọ́ náà padà sí abẹ́ aṣọ ní igbá àyà rẹ.” Mose sì ṣe bẹ́ẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ sì padà bọ́ sípò bí àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ tókù.
8 To pacoengah Angraeng mah, Nang to tang o ai moe, kaom hmaloe ih angmathaih to tang o ai cadoeh, hnukkhuem ih angmathaih loe nihcae mah tang o tih.
Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, “Bí wọn kò bá gbà ọ́ gbọ́ tàbí kọ ibi ara sí iṣẹ́ ìyanu àkọ́kọ́, wọ́n le è ti ipasẹ̀ iṣẹ́ ìyanu kejì gbàgbọ́.
9 Toe vai hnetto haih angmathaih to ni nihcae mah tang o ai moe, na lok to tahngai o ai nahaeloe, Vapui ih tui to doh ah loe, karoem long ah krai ah; to naah vapui ah na dok ih tui to karoem long nuiah athii ah angcoeng tih, tiah a naa.
Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá gba àmì méjèèjì wọ̀nyí gbọ́, tí wọn kò sì fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ, bu omi díẹ̀ láti inú odò Naili kí o si dà á sí orí ìyàngbẹ ilẹ̀, omi tí ìwọ bù láti inú odò yìí yóò sì di ẹ̀jẹ̀.”
10 Mosi mah Angraeng khaeah, Aw Angraeng, kai loe lok ka thui thai ai; canghniah, na tamna khaeah lok nang thuih pacoengah doeh, lok hae ka thui thai ai; ka lok hae tongaah moe, lok ka pae thai ai, tiah a naa.
Mose sì sọ fún Olúwa pé, “Èmi jẹ́ akólòlò, èmi kì í ṣe ẹni tó lè sọ̀rọ̀ já gaara láti ìgbà àtijọ́ wá tàbí láti ìgbà ti o ti ń bá ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀, mo jẹ́ ẹni ti ahọ́n rẹ̀ lọ́, tí ó sì ń lọ́ra àti sọ̀rọ̀.”
11 Angraeng mah anih khaeah, Kami ih pakha, to tih ai boeh loe lokaa hoi naapang, to tih ai boeh loe kamtueng mik hoi mikmaeng to mi mah maw sak? Kai, Angraeng mah na ai maw sak?
Olúwa sì sọ fún un pé, “Ta ni ó fún ènìyàn ni ẹnu? Ta ni ó mú un ya odi tàbí adití? Ta ni ó mú un ríran, tàbí mú un fọ́jú? Ǹjẹ́ kì í ṣe èmi Olúwa?
12 To pongah vaihi caeh ah, na pakha ah Ka oh moe, timaw thuih han tito kang patuk han, tiah a naa.
Lọ nísinsin yìí, Èmi yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò sì kọ́ ọ ni ohun ti ìwọ yóò sọ.”
13 Toe Mosi mah, Aw Angraeng, minawk kalah patoeh halat ah, tiah a naa.
Mose dáhùn ó wí pé, “Olúwa jọ̀wọ́ rán ẹlòmíràn láti lọ ṣe iṣẹ́ yìí.”
14 To naah Mosi nuiah Angraeng palungphui moe, Levi kami, nam ya Aaron oh maw? Anih loe lokthuih thaih, tiah ka panoek. Khenah, anih loe nang tongh hanah loklam ah angzoh li vop; anih mah nang to hnuk naah anghoe tih.
Ìbínú Olúwa ru sókè sí Mose, ó sì sọ pé, “Aaroni ará Lefi arákùnrin rẹ ń kọ́? Mo mọ̀ pé ó lè sọ̀rọ̀ já gaara, ó ti wà ní ọ̀nà rẹ̀ báyìí láti pàdé e rẹ. Inú rẹ̀ yóò sì dùn ti ó bá rí ọ.
15 Anih hoi lok aram hoiah loe, a thuih han koi lok to thui paeh; kai loe na pakha hoi anih ih pakha ah ka oh moe, na sak hoi han koi hmuen to kang patuuk han.
Ìwọ yóò sọ̀rọ̀ fún un, ìwọ yóò sì fi ọ̀rọ̀ sí i lẹ́nu, èmi yóò ràn yín lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò kọ́ ọ yín ni ohun ti ẹ ó ṣe.
16 Anih loe kaminawk hmaa ah nang han lokthui kami ah om tih; anih loe na pahni zuengah om ueloe, nang doeh anih han Sithaw zuengah om tih.
Òun yóò bá ọ sọ̀rọ̀ sí àwọn ènìyàn, yóò sì dàbí i pé ẹnu un rẹ ni a gbà sọ ọ̀rọ̀ náà, ìwọ yóò sì dàbí Ọlọ́run ní iwájú rẹ̀.
17 Dawnrai angmathaih hmuennawk na sak hanah, hae cunghet hae na ban ah sin ah, tiah a naa.
Ṣùgbọ́n mú ọ̀pá yìí ni ọwọ́ rẹ kí ìwọ bá à lè fi ṣe àwọn iṣẹ́ àmì ìyanu pẹ̀lú rẹ̀.”
18 Mosi loe amsae Jethro khaeah amlaem moe, anih khaeah, Izip prae ah kaimah ih nawkamyanawk hing o vop maw, tiah khet hanah, na caehsak raeh, tiah a naa. Jethro mah, Lunghoihta hoi caeh ah, tiah a naa.
Mose padà sí ọ̀dọ̀ Jetro baba ìyàwó rẹ̀, ó sì sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ jẹ́ kí n padà tọ àwọn ènìyàn mi lọ ni ilẹ̀ Ejibiti láti wò bóyá wọ́n ṣì wà láààyè síbẹ̀.” Jetro sì dáhùn, ó wí pé, “Máa lọ ni àlàáfíà.”
19 Midian prae ah oh naah, Angraeng mah Mosi khaeah, Izip prae ah caeh let ah, na hinghaih pakrong kaminawk loe duek o boih boeh, tiah a naa.
Nísinsin yìí, Olúwa ti sọ fún Mose ni ilẹ̀ Midiani pé, “Máa padà lọ sí Ejibiti, nítorí àwọn ti ó fẹ́ pa ọ ti kú.”
20 To pongah Mosi mah a zu hoi a capanawk to kawk moe, Laa hrang pongah angthuengsak, Sithaw ih cunghet to a ban ah sin moe, Izip prae ah amlaem let.
Mose mú ìyàwó rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó kó wọn lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sì bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ̀ padà sí Ejibiti. Ó sì mú ọ̀pá Ọlọ́run sí ọwọ́ rẹ̀.
21 Angraeng mah Mosi khaeah, Izip prae ah nam laem let naah, Na ban ah kang suek ih dawnrai hmuennawk to Faro hmaa ah sah paeh; toe anih mah Israel kaminawk caehsak han ai ah, anih ih palung to kam taksak han.
Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Ní ìgbà tí ìwọ bá padà sí Ejibiti rí i pé ìwọ ṣe iṣẹ́ ìyanu ni iwájú Farao. Èmi ti fún ọ lágbára láti ṣe é. Èmi yóò sì sé àyà rẹ̀ le, òun kì yóò jẹ́ kí àwọn ènìyàn náà kí ó lọ.
22 To naah Faro khaeah, Angraeng mah, Israel loe ka capa hoi ka calu ah oh;
Lẹ́yìn náà, kí o sọ fún Farao pé, ‘Èyí ni Olúwa sọ: Israẹli ní àkọ́bí ọmọ mi ọkùnrin,
23 Ka capa mah ka tok to sak hanah, prawt ah, tiah lok kang thuih; to tiah na prawt ai nahaeloe, na capa, na calu to ka hum han, tiah thui paeh, tiah Mosi khaeah a thuih pae.
mo sọ fún ọ, “Jẹ́ kí ọmọ mi lọ, ki òun kí ó lè máa sìn mí.” Ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ láti jẹ́ kí ó lọ; nítorí náà, èmi yóò pa àkọ́bí ọmọ rẹ ọkùnrin.’”
24 A ohhaih im loklam ah caeh naah, Angraeng mah Mosi to hnuk moe, anih to hum hanah patoem.
Ní ọ̀nà ìrìnàjò rẹ, ni ibi tí wọ́n gbé sùn ní ilé èrò ní alẹ́, Olúwa pàdé Mose, ó sì fẹ́ láti pa á.
25 Toe Zipporah mah thlung kanoe to lak moe, a capa ih tangzat hin to aah pacoengah, Mosi khokkung ah akuep moe, Nang loe athii kalong ka sava ah na oh, tiah a naa.
Ṣùgbọ́n Sippora mú ọ̀bẹ òkúta mímú, ó sì kọ ọmọ rẹ̀ ní ilà abẹ́, ó sì fi awọ rẹ̀ kan ẹsẹ̀ Mose. Sippora sì wí pé, “Ọkọ ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ jẹ́ sí mi.”
26 To pongah Angraeng mah Mosi to loihsak; tangzat hin aahhaih athii pongah ni, a zu mah nang loe athii kalong ka sava ah na oh, tiah a naa.
Nítorí náà Olúwa yọ̀ǹda rẹ láti ìgbà tí ó ti wí pé, “Ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ í ṣe.” Èyí tó túmọ̀ sí ìkọlà abẹ́.
27 Angraeng mah Aaron khaeah, Mosi tongh hanah praezaek ah caeh ah, tiah a naa. To pongah anih loe caeh, Mosi to Sithaw mae ah tongh moe, anih to mok.
Olúwa sì sọ fún Aaroni pé, “Lọ sínú aginjù láti lọ pàdé Mose.” Ní ìgbà náà ni ó lọ pàdé Mose ní orí òkè Ọlọ́run, ó sì fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
28 To naah Mosi mah Aaron khaeah, Anih patoehkung Angraeng mah thuih ih loknawk boih, a sak han koi dawnrai hmuennawk to a thuih pae boih.
Ní ìgbà náà ni Mose sì sọ ohun gbogbo tí Ọlọ́run ti rán fún Aaroni àti nípa gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí Olúwa ti pàṣẹ fún un láti ṣe ní iwájú Farao.
29 Mosi hoi Aaron loe caeh hoi moe, Israel kacoehtanawk to kawk boih pacoengah, nawnto amkhuengsak.
Mose àti Aaroni pe gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli jọ.
30 Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih loknawk to Aaron khaeah a thuih pae boih, kaminawk hmaa ah dawnrai hmuennawk doeh a sak pae.
Aaroni sọ ohun gbogbo tí Olúwa sọ fún Mose fún wọn, ó sì ṣe iṣẹ́ àmì náà ní ojú àwọn ènìyàn náà.
31 To naah kaminawk mah tang o; Angraeng loe Israel kaminawk khet hanah angzoh, tiah panoek o moe, nihcae patangkhanghaih to a hnuk pae, tiah a thaih o naah, nihcae mah long ah lu akuephaih hoiah bok o.
Wọ́n sì gbàgbọ́. Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé Olúwa ti bẹ àwọn ọmọ Israẹli wò àti pé Olúwa ti gbọ́ nípa ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sì sìn ín. Ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ àmì náà níwájú àwọn ènìyàn náà.

< Exodus 4 >