< Exodus 2 >

1 To nathuem ah Levi kami maeto mah, Levi canu to zu ah lak.
Ó sì ṣe, ọkùnrin ará ilé Lefi kan fẹ́ ọmọbìnrin ará Lefi kan ni ìyàwó.
2 A zu loe zokpom moe, caa nongpa maeto sak; a khet naah nawkta loe kranghoih parai; to pongah anih to khrah thumto thung a hawk.
Obìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Nígbà tí ó rí í pé ọmọ náà rẹwà, ó gbé ọmọ náà pamọ́ fún oṣù mẹ́ta.
3 Toe hawk thai laek ai naah loe, sakrung kung hoiah sak ih thingkhong maeto a lak moe, tuipan hoi thing tangpri hoiah a bet caeng, nawkta to thingkhong thungah suek moe, vapui taengah a bangh.
Ṣùgbọ́n nígbà tí kò le è gbé e pamọ́ mọ́, ó fi ewé papirusi hun apẹ̀rẹ̀, ó sì fi ọ̀dà àti òjé igi sán apẹ̀rẹ̀ náà. Ó sì tẹ́ ọmọ náà sínú rẹ̀, ó sì gbe é sí inú eèsún ni etí odò Naili.
4 Anih ih tanuh mah kawbang maw oh, tiah panoek hanah, ahmuen kangthla hoiah khet.
Arábìnrin rẹ̀ dúró ni òkèèrè láti wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọmọ náà.
5 Faro canu loe tui amthluk hanah vapui ah caeh tathuk; to naah a tamna nongpatanawk loe tui taengah amkaeh o; anih mah tui taeng ih thingkhong to hnuk naah, a tamna nongpata maeto khaeah laksak.
Nígbà náà ni ọmọbìnrin Farao sọ̀kalẹ̀ wá sí etí odò Naili láti wẹ̀, àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ sì ń rìn ni etí bèbè odò. Ó sì ri apẹ̀rẹ̀ náà ni àárín eèsún, ó sì rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin kan láti lọ gbé e wá,
6 Anih mah thingkhong to paongh naah, nawkta to a hnuk; kaqah nawkta to a hnuk naah, tahmen moe, Hae loe Hebru nawkta bae hae, tiah a thuih.
ó ṣí i, ó sì rí ọmọ náà. Ọmọ náà ń sọkún, àánú ọmọ náà sì ṣe é. Ó wí pé, “Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Heberu ni èyí.”
7 To naah anih ih tanuh mah Faro canu khaeah, Nang han nawkta khenzawnkung Hebru nongpatanawk to kang kawk pae han maw? tiah a naa.
Nígbà náà ni arábìnrin rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ ọmọbìnrin Farao pé, “Ṣé kí èmi lọ wá ọ̀kan lára àwọn obìnrin Heberu wá fún ọ láti bá ọ tọ́jú ọmọ náà?”
8 Anih mah, Caeh ah loe, kawk ah, tiah a naa. Tamna nongpata loe caeh moe, nawkta ih amno to kawk.
Ó sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni; lọ.” Arábìnrin náà sì lọ, ó sì pe ìyá ọmọ náà wá.
9 Faro canu mah anih khaeah, Hae nawkta hae la ah loe, kai hanah com ah, atho kang paek han hmang, tiah a naa. To pongah nongpata mah nawkta to lak moe, khetzawn pae.
Ọmọbìnrin Farao sì wí fún un pé, “Gba ọmọ yìí kí o sì tọ́jú rẹ̀ fún mi, èmi yóò san owó iṣẹ́ ẹ̀ rẹ fún ọ.” Ọmọbìnrin náà sì gbé ọmọ náà lọ, ó sì tọ́jú rẹ̀.
10 Nawkta qoeng tahang naah loe, Faro canu khaeah caeh haih moe, anih ih capa ah angcoeng. Nongpata mah tui thung hoiah ka khuih, tiah a thuih pongah, anih to Mosi, tiah ahmin phui.
Nígbà tí ọmọ náà sì dàgbà, ó mú un tọ ọmọbìnrin Farao wá, ó sì di ọmọ rẹ̀. Ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Mose, ó wí pé, “Nítorí tí mo fà á jáde nínú omi.”
11 Mosi qoeng tahang naah loe, angmah ih acaeng nawkamyanawk toksakhaih ahmuen ah caeh; to nathuem ah nihcae loe karai parai tok a sak o, tiah Mosi mah hnuk; to naah Izip kami maeto mah anih ih nawkamya Hebru kami to boh.
Ní ọjọ́ kan, nígbà tí Mose ti dàgbà, ó jáde lọ sí ibi ti àwọn ènìyàn rẹ̀ wà, ó ń wò wọ́n lẹ́nu iṣẹ́ líle wọn, ó ri ará Ejibiti tí ń lu ará Heberu, ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.
12 Ahnuk ahmaa a khet naah, mi doeh hnu ai pongah, Izip kami to a hum moe, savuet thungah aphum.
Ó wo ìhín, ó wo ọ̀hún, nígbà tí kò rí ẹnìkankan, ni ó bá pa ará Ejibiti náà, ó sì bò ó mọ́ inú iyanrìn.
13 Khawnbang ni hnetto naah a caeh let, to naah kangpanh Hebru kami hnik to a hnuk let bae; anih mah hmuen sah pazae kami khaeah, Tipongah nam pui Hebru kami to na boh loe? tiah a naa.
Ní ọjọ́ kejì, ó jáde lọ, ó rí àwọn ará Heberu méjì tí wọ́n ń jà. Ó béèrè lọ́wọ́ èyí tí ó jẹ̀bi pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń lu Heberu arákùnrin rẹ?”
14 To kami mah, Mi mah maw nang hae kaihnik ukkung hoi lokcaekkung ah suek? Izip kami na hum baktih toengah, kai doeh hum han nang patoem maw? tiah a naa. Mosi mah to lok to thaih naah tasoeh moe, Ka sak ih hmuen angphong tih boeh, tiah poek.
Ọkùnrin náà sì dáhùn pé, “Ta ni ó fi ọ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa? Ṣé ìwọ fẹ́ pa mí bí o ti pa ará Ejibiti?” Nígbà náà ni ẹ̀rù ba Mose, ó sì wí pé, “Lóòótọ́ ni ọ̀ràn yìí ti di mí mọ̀.”
15 Faro mah to kawng to thaih naah Mosi to hum hanah pakrong. Toe Mosi loe Faro hmaa hoiah cawnh moe, Midian prae ah khosak; to ah tui khaw taengah anghnut.
Nígbà ti Farao sì gbọ́ nípa èyí, ó wá ọ̀nà láti pa Mose, ṣùgbọ́n Mose sá kúrò ní àrọ́wọ́tó o Farao, ó lọ sí Midiani láti máa gbé, nígbà tí ó dé bẹ̀, ó jókòó ni ẹ̀bá a kànga kan.
16 Midian prae ih qaima loe canu sarihto tawnh; anih ih canunawk loe tuidok hanah tui khaw ah caeh o moe, ampa ih tuunawk to tui a paek o.
Ó sì ṣe, àlùfáà Midiani kan ni àwọn ọmọbìnrin méje, wọn sì wá láti pọn omi kún ọpọ́n ìmumi fún ẹran ọ̀sìn baba wọn.
17 To naah tuu toep kaminawk to angzoh o moe, tuunawk to huih pae o ving; toe Mosi mah angdoet moe, nongpatanawk to angsak haih pacoengah, tuunawk to tui a naeksak.
Àwọn darandaran kan wá, wọ́n sì lé wọn sẹ́yìn, ṣùgbọ́n Mose dìde láti gbà wọ́n sílẹ̀ àti láti ràn wọ́n lọ́wọ́ láti fún ẹran wọn ní omi.
18 Tanglanawk loe ampa, Reuel khaeah amlaem o let, to naah ampa mah tikhoe vaihni loe nam laem o palang takan loe? tiah a naa.
Nígbà ti àwọn ọmọbìnrin náà padà dé ọ̀dọ̀ Reueli baba wọn, ó béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi tètè dé ni òní?”
19 To naah nihcae mah, Izip kami maeto mah tuu toep kaminawk ih ban thung hoiah ang pahlong pongah kam laem o palang, anih mah ni tui dok moe, tuunawk doeh tui a paek, tiah a naa o.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ará Ejibiti kan ni ó gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn darandaran, ó tilẹ̀ ràn wá lọ́wọ́ láti fa omi àti láti fún agbo ẹran ní omi.”
20 To naah anih mah a canunawk khaeah, Anih loe naa ah maw oh? Tikhoe na caeh o taak sut loe? Buhcaak han kawk o khae, tiah a naa.
Ó sọ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀, “Níbo ni ó wà? Èéṣe ti ẹ fi fi ọkùnrin náà sílẹ̀? Ẹ pè é wá jẹun.”
21 Mosi loe to kami ih im ah oh han koeh pongah, ampa mah a canu Zipporah to Mosi hanah zu ah paek.
Mose gbà láti dúró lọ́dọ̀ ọkùnrin náà, ẹni tí o fi Sippora, ọmọbìnrin rẹ̀ fún Mose láti fi ṣe aya.
22 Zipporah mah anih han caa nongpa maeto sak pae, Minawk prae ah angvin ah ka oh, tiah a thuih pongah, Gershom, tiah ahmin phui.
Ó sì bí ọmọkùnrin kan tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní Gerṣomu, ó wí pé, “Èmi ń ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì.”
23 To tiah atue kasawk ah oh na thungah, Izip siangpahrang to duek; Israel kaminawk loe misong ah ohhaih to anghmawt o sut boeh pongah, a qah o; misong ah kaom kaminawk qahhaih lok to Sithaw mah thaih pae.
Lẹ́yìn ìgbà pípẹ́, ọba Ejibiti kú. Àwọn ará Israẹli ń kérora ní oko ẹrú wọn, wọ́n ń ké fún ìrànlọ́wọ́ nítorí oko ẹrú tí wọ́n wà, igbe wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ Ọlọ́run.
24 Nihcae hanghaih lok Sithaw mah thaih naah, Abraham, Issak hoi Jakob khaeah sak ih lokkamhaih to a poek let.
Ọlọ́run gbọ́ igbe wọn, Ó sì rántí májẹ̀mú rẹ̀ pẹ̀lú Abrahamu, Isaaki àti pẹ̀lú Jakọbu.
25 To pongah Sithaw mah Israel kaminawk to khet tathuk moe, nihcae han kho poek pae.
Nítorí náà, Ọlọ́run bojú wo àwọn ará Israẹli, Ó sì wà láti gbà wọ́n sílẹ̀.

< Exodus 2 >