< 2 Siangpahrang 17 >

1 Judah siangpahrang Ahaz saning hatlaihnetto haih naah, Elah capa Hoshea loe Samaria vangpui ah Israel siangpahrang ah oh, anih mah saning takawtto thung uk.
Ní ọdún kejìlá ọba Ahasi ará Juda, Hosea ọmọ Ela jẹ ọba Israẹli ní Samaria, ó sì jẹ fún ọdún mẹ́sàn-án.
2 Anih loe Angraeng mikhnukah kahoih ai hmuen to sak; hmaloe ih kaom Israel siangpahrangnawk baktiah hmuen to sah ai.
Ó sì ṣe búburú ní ojú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe bí i ti ọba Israẹli ẹni tí ó ti wà ṣáájú rẹ̀.
3 Assyria siangpahrang Shalmaneser mah, Hoshea to tuk moe, tamna ah suek pacoengah, tamut to paeksak.
Ṣalamaneseri ọba Asiria wá sókè láti mú Hosea, ẹni tí ó ti jẹ fún Ṣalamaneseri ó sì ti san owó òde fún un.
4 Hoshea loe saning kruek paek han koi tamut to paek ai, anih mah Izip siangpahrang So khaeah laicaeh patoeh moe, misatuk han pacaeng ti, tiah Assyria siangpahrang mah panoek naah, anih to naeh moe, thongim thungah pakhrak.
Ṣùgbọ́n ọba Asiria rí i wí pé Hosea jẹ́ ọlọ́tẹ̀, nítorí ó ti rán oníṣẹ́ sọ́dọ̀ ọba Ejibiti, kò sì san owó òde mọ́ fún ọba Asiria, gẹ́gẹ́ bí o ti máa ń ṣe ní ọdọọdún. Nígbà náà ọba Asiria fi agbára mú ún, ó sì fi sínú túbú.
5 Assyria siangpahrang loe prae boih tuk hanah angzoh tahang; Samaria vangpui ah caeh moe, vangpui to saning thumto thung takui.
Ọba Asiria gòkè wá sí gbogbo ibi ilé náà, ó sì lọ sí Samaria, ó sì dúró tí ì fún ọdún mẹ́ta.
6 Hoshea siangpahrang ah ohhaih saning takawtto naah, Assyria siangpahrang mah Samaria to lak moe, Israel kaminawk to Assyria ah caeh haih; nihcae to Gozan vapui taeng, Medes kaminawk ih vangpui Halah hoi Habor ah ohsak.
Ní ọdún kẹsànán ti Hosea, ọba Asiria mú Samaria ó sì kó Israẹli lọ sí Asiria. Ó sì fi wọ́n sílẹ̀ ní Hala, ní Gosani ní etí odò Habori àti ní ìlú àwọn ará Media.
7 Israel kaminawk loe Izip prae hoi Izip siangpahrang Faro ban thung hoiah zaehoikung, angmacae Angraeng Sithaw hmaa ah zaehaih to sak o moe, kalah sithawnawk to bok o taak,
Gbogbo eléyìí ṣẹlẹ̀ nítorí àwọn ọmọ Israẹli ti dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni tí ó mú wọn jáde ní Ejibiti lábẹ́ agbára Farao ọba Ejibiti. Wọ́n sin ọlọ́run mìíràn,
8 Israel caanawk hoi angmacae mah suek o ih, Israel siangpahrangnawk hmaa ah, Angraeng mah haek ih sithaw panoek ai kaminawk mah sak o ih atawk to pazui o.
wọn si tẹ̀lé ìwà orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti gbá kúrò níwájú wọn gẹ́gẹ́ bí ìwà ti ọba Israẹli tí ó ti paláṣẹ.
9 Israel kaminawk loe angmacae Angraeng Sithaw mah koeh ai ih hmuen to tamquta hoiah sak o; misatoephaih imsang hoi vangpui sipaenawk to a sak o moe, avangnawk boih ah hmuensang to a sak o.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun ìríra sí Olúwa Ọlọ́run wọn kọ́ láti ilé ìṣọ́ sí ìlú tí a dáàbò bò, wọ́n kọ́ ilé gíga fún ara wọn ní gbogbo ìlú wọn.
10 Krang hoi Asherah krang soi ih thingnawk to maesom nui hoi thingkung tlim boi ah a suek o.
Wọ́n sì gbé àwọn òkúta tí a yà sọ́tọ̀ sókè àti ère òrìṣà Aṣerah lórí gbogbo igi tútù.
11 Nihcae hmaa ah Angraeng Sithaw mah haek ih, Sithaw panoek ai kaminawk mah sak ih hmuen baktih toengah, hmuensang boih ah hmuihoih to thlaek o moe, Angraeng palungphuisak hanah, kahoih ai hmuen to a sak o.
Ní gbogbo ibi gíga, wọ́n sun tùràrí gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti lé jáde níwájú wọn. Wọ́n ṣe ohun búburú tí ó rú ìbínú Olúwa sókè.
12 Angraeng mah, Hae hmuennawk hae sah o hmah, tiah thuih pae; toe krang to a bok o toengtoeng vop.
Wọ́n sìn òrìṣà, èyí tí Olúwa ti sọ pé, “Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe èyí.”
13 Angraeng Sithaw mah, Kahoih ai loklam to caeh o taak ah loe, nam panawk khaeah ka thuih ih dannawk boih, tahmanawk rang hoiah thuih ih ka lokpaekhaih hoi ka thuitaekhaih loknawk to pazui oh, tiah ka tamna tahmanawk patohhaih rang hoiah Israel hoi Judah kaminawk khaeah ka thuih.
Olúwa kìlọ̀ fún Israẹli àti Juda nípa gbogbo àwọn wòlíì wọn àti aríran: “Ẹ yípadà kúrò ní ọ̀nà búburú yín. Kí ẹ ṣe òfin mi àti ìlànà mi, ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo òfin tí Èmi paláṣẹ fún àwọn baba yín láti tẹ̀lé àti èyí tí mo rán sí i yín nípa ìránṣẹ́ àwọn wòlíì mi.”
14 Toe nihcae mah tahngai o ai; angmacae Angraeng Sithaw katang ai, ampanawk baktiah palungthin amtak o sak.
Ṣùgbọ́n wọn kò ní gbọ́, wọ́n sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ọlọ́rùn líle gẹ́gẹ́ bí i ti baba wọn, ẹni tí kò gbà Olúwa Ọlọ́run wọn gbọ́.
15 Ampanawk khaeah sak ih lokmaihaih hoi patuk ih lok to nihcae mah pahnawt o, Anih mah thuih pae ih a thuitaekhaih loknawk doeh nihcae mah tahngai pae o ai; nihcae loe avang ai krangnawk hnuk ah bang o pongah, tidoeh avang ai ah oh o; Angraeng mah nihcae taeng kaom Sithaw panoek ai kaminawk mah sak ih hmuen baktiah sah o hmah, tiah a naa; toe nihcae hnukah patom o.
Wọ́n kọ̀ ìlànà rẹ̀ àti májẹ̀mú tí ó ti ṣe pẹ̀lú baba wọn àti ìkìlọ̀ tí ó ti fi fún wọn. Wọ́n tẹ̀lé òrìṣà aláìníláárí, àwọn fún rara wọn sì jẹ́ aláìníláárí. Wọ́n tẹ̀lé orílẹ̀-èdè tí ó yí wọn ká bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olúwa ti kìlọ̀ fún wọn pé, “Má ṣe ṣe gẹ́gẹ́ bí wọn tí ń ṣe,” wọ́n sì ṣe ohun tí Olúwa ti kà léèwọ̀ fún wọn láti ṣe.
16 Angmacae Angraeng Sithaw mah paek ih loknawk to pahnawt o, angmacae hanah maitaw caa krang hnetto a sak o moe, Asherah thing maeto a tling o; cakaehnawk boih to bok o moe, Baal ih tok to sak pae o.
Wọ́n kọ̀ gbogbo òfin Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, wọ́n sì ṣe òrìṣà méjì fún ara wọn, wọ́n sì gbẹ́ ẹ ọ̀kan ní ère ẹgbọrọ màlúù, àti ọ̀kan ní ère òrìṣà Aṣerah. Wọ́n sì tẹrí wọn ba sí gbogbo ogun ọ̀run, wọ́n sì sin Baali.
17 A canu hoi a capanawk to hmai angbawnhaih sak hanah patoh o moe, taqawk thacakhaih hoi angzo han koi hmuen taphonghaih, adoi hoi sak ih hmuennawk to patoh o, Angraeng palungphuisak hanah, Angraeng mikhnukah angmacae hoi angmacae to kahoih ai hmuen sak hanah ang zawh o.
Wọ́n sì fi àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn rú ẹbọ nínú iná. Wọ́n sì ń fọ àfọ̀ṣẹ, wọ́n sì ń ṣe àlúpàyídà wọ́n sì ta ara wọn láti ṣe ohun búburú níwájú Olúwa, wọ́n sì mú un bínú.
18 To pongah Angraeng loe Israel nuiah paroeai palungphui moe, nihcae to angmah hmaa hoiah takhoe king; Judah acaeng khue to a suek.
Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa sì bínú gidigidi pẹ̀lú Israẹli ó sì mú wọn kúrò níwájú rẹ̀. Ẹ̀yà Juda nìkan ṣoṣo ni ó kù,
19 Judah kaminawk loe angmacae Angraeng Sithaw mah paek ih lok to pazui o ai; Israel kaminawk caehhaih loklam to pazui o lat.
àti pẹ̀lú, Juda kò pa òfin Olúwa Ọlọ́run wọn mọ́. Wọ́n tẹ̀lé ìhùwàsí àwọn Israẹli tí wọ́n ṣe.
20 To pongah Angraeng mah Israel kaminawk boih to pahnawt moe, nihcae to patangkhangsak; a hmaa hoiah takhoe boih ai karoek to, nihcae to parokungnawk ban ah a paek.
Nítorí náà Olúwa kọ gbogbo àwọn ènìyàn Israẹli; ó sì jẹ wọ́n ní yà. Ó sì fi wọ́n lé ọwọ́ àwọn olè títí tí ó fi ta wọ́n nù kúrò níwájú rẹ̀.
21 Angraeng mah Israel kaminawk to David imthung takoh thung hoiah tapraek pongah, nihcae mah Nebat capa Jeroboam to siangpahrang ah suek o; Jeroboam mah Angraeng hnukah kabang Israel kaminawk to loklam amkhraengsak, anih mah to baktih kalen parai zaehaih to saksak.
Nígbà tí ó ta Israẹli kúrò láti ìdílé Dafidi, wọ́n sì mú Jeroboamu ọmọ Nebati jẹ ọba wọn. Jeroboamu sì mú kí àwọn ọmọ Israẹli yípadà kúrò ní títẹ̀lé Olúwa, ó sí mú kí wọn dẹ́ṣẹ̀ ńlá.
22 Israel kaminawk loe Jeroboam mah sak ih zaehaih to caeh o taak ai, pazui o toengtoeng vop.
Àwọn ọmọ Israẹli forítì í nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu kò sì yí padà kúrò lọ́dọ̀ wọn,
23 Angraeng mah a tamna tahmaanawk patohhaih rang hoiah thuih ih lok baktih toengah, Israel kaminawk to angmah hmaa hoiah takhoe boih ai karoek to, to zaehaih to nihcae mah sak o. To pongah Israel kaminawk loe angmacae prae thung hoiah Assyria prae ah misong ah caeh o haih, vaihni ni khoek to to ah oh o.
títí tí Olúwa fi mú wọn kúrò níwájú rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti paláṣẹ láti ọ̀dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ wòlíì. Bẹ́ẹ̀ ni a kó gbogbo ènìyàn Israẹli kúrò ní ilẹ̀ wọn lọ sí ìgbèkùn ni Asiria, títí di òní yìí.
24 Assyria siangpahrang mah Babylon, Kuthah, Ava, Hammath hoi Sepharviam prae ih kaminawk to hoih moe, Israel kaminawk zuengah, Samaria vangpui ah khosaksak. Nihcae mah Samaria to lak o moe, to vangpuinawk boih khosak o.
Ọba Asiria mú àwọn ènìyàn láti Babeli, Kuta, Afa, Hamati àti Sefarfaimi, wọ́n sì fi wọ́n sínú ìlú Samaria láti rọ́pò àwọn ọmọ Israẹli. Wọ́n sì ń gbé ní ìlú náà.
25 To ah khosak o tangsuek naah, Angraeng to zii o ai; to pongah Angraeng mah kaipuinawk to patoeh moe, thoemto kaminawk to kaek.
Nígbà tí wọ́n gbé bẹ̀ ní àkọ́kọ́, wọn kò sì bẹ̀rù Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni ó rán kìnnìún sí àárín wọn. Wọ́n sì pa nínú wọn.
26 To pongah thoemto kaminawk mah, Na patoeh moe, Samaria vangpui ah na ohsak ih kaminawk loe prae thungah kaom Sithaw to panoek o ai pongah, khenah, Sithaw mah kaipuinawk to patoeh moe, vangpui thungah kaom kaminawk to kaek boeh, tiah Assyrian siangpahrang khaeah thuih pae o.
Wọ́n sì sọ fún ọba Asiria pé, “Àwọn ènìyàn tí ìwọ lé kúrò tí o sì fi sínú ìlú Samaria kò mọ ohun tí ọlọ́run ìlú náà béèrè. Ó sì ti rán kìnnìún sí àárín wọn, tí ó sì ń pa wọ́n run, nítorí ènìyàn wọn kò mọ ohun tí ó béèrè.”
27 To pacoengah Assyria siangpahrang mah, Samaria hoiah na hoih o ih qaima maeto vangpui ah oh hanah, patoeh o let ah, anih mah to prae thungah kaom Sithaw koehhaih to patuk nasoe, tiah a naa.
Nígbà náà ọba Asiria pàṣẹ yìí wí pé, “Mú ọ̀kan lára àwọn àlùfáà tí ó mú láti Samaria lọ padà gbé níbẹ̀ kí ó sì kọ́ àwọn ènìyàn ní, ohun tí ọlọ́run ilẹ̀ náà béèrè.”
28 To pacoengah Samaria vangpui hoiah hoih o ving ih, qaima maeto loe Bethel ah oh hanah caeh, anih mah Angraeng zit han angaih kawng to patuk.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan lára àwọn àlùfáà tí ó ti kúrò ní Samaria wá gbé ní Beteli ó sì kọ́ wọn bí a ti ń sin Olúwa.
29 Toe to ah kaom acaeng kaminawk boih loe, angmacae ohhaih ahmuen kruekah angmacae ih sithawnawk to sak o; Samaria kaminawk mah sak o ih sithawnawk to hmuensang kruekah a suek o.
Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, olúkúlùkù orílẹ̀-èdè ṣe òrìṣà tirẹ̀ ní gbogbo ìlú níbi tí wọ́n gbé wà, wọ́n sì gbé wọn nínú ilé òrìṣà àti àwọn ènìyàn Samaria ó sì ṣe wọ́n sí ibi gíga wọ̀n-ọn-nì.
30 Babylon ih kaminawk mah Sukkoth-Benoth to sak o; Kuthah ih kaminawk mah Nergal to sak o; Hummath ih kaminawk mah Ashima to sak o;
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin láti Babeli ṣe àgọ́ àwọn wúńdíá, àwọn ènìyàn Kuti ṣe òrìṣà Nergali, àti àwọn ènìyàn Hamati ṣe ti Aṣima;
31 Ava ih kaminawk mah Nibhaz hoi Tartak to sak o; Sepharvaim ih kaminawk mah loe Sepharvaim sithaw ah kaom, Adrammelek hoi Anamelek khaeah hmai angbawnhaih sak hanah a caanawk to patoh o.
àti àwọn ará Afa ṣe Nibhasi àti Tartaki, àti àwọn ará Sefarfaimi sun àwọn ọmọ wọn níná gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sí Adrameleki àti Anameleki, àwọn òrìṣà Sefarfaimi.
32 Nihcae mah Angraeng to zit o; toe angmacae ih kaminawk boih to angmacae bokhaih hmuensang ih qaima ah suek o.
Wọ́n sin Olúwa, ṣùgbọ́n wọ́n sì tún yan gbogbo ẹgbẹ́ tí ènìyàn wọn láti ṣe iṣẹ́ oyè fún wọn gẹ́gẹ́ bí àlùfáà ní ibi gíga.
33 Nihcae mah Angraeng to zit o; toe misong ah hoih ih kaminawk mah sak ih baktih toengah, angmacae sithawnawk ih tok to a sak o.
Wọ́n sin Olúwa ṣùgbọ́n wọ́n sin òrìṣà wọn ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú àṣà orílẹ̀-èdè wọn láti ibi tí wọ́n ti gbé wọn wá.
34 Vaihni ni khoek to canghnii ah a sak o ih hmuen to sak o vop; Angraeng to zii o ai; Israel kaminawk han paek ih loknawk, sakzong ih atawknawk doeh pazui o ai; Israel, tiah ahmin paek ih Jakob caanawk khaeah, Angraeng mah paek ih loknawk doeh pazui o ai.
Láti ìgbà náà wá àwọn àlùfáà wọn ṣe bí ti àtẹ̀yìnwá. Wọn kò sin Olúwa tàbí kí wọ́n fi ara mọ́ ìlànà àti àṣẹ àti òfin tí Olúwa fi fún ìránṣẹ́ Jakọbu, tí wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ní Israẹli.
35 Angraeng mah Israel kaminawk hoi lokmaihaih sak naah, nihcae khaeah, Kalah sithawnawk to bok o hmah; a hmaa ah akuep o hmah; nihcae ih tok to sah pae o hmah; angbawnhaih doeh sah o hmah;
Nígbà tí Olúwa ṣe májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn ọmọ Israẹli ó pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe sin òrìṣà mìíràn tàbí tẹríba fún wọn, sìn wọ́n tàbí kí ẹ rú ẹbọ sí wọn.
36 toe thacakhaih ban hoi Izip prae thung hoiah nangcae zaehoikung to bok oh; anih khaeah akuep oh loe, anih khaeah angbawnhaih to sah oh, tiah a naa.
Ṣùgbọ́n Olúwa, ẹni tí ó mú yín gòkè jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú agbára ńlá àti nínà apá, òun ni ẹni náà tí ó yẹ kí ẹ sìn. Òun ni ẹni tí ó yẹ kí ẹ tẹríba fún àti sí òun ni kí ẹ rú ẹbọ fún.
37 Nangcae han ka tarik ih, lokpaekhaih hoi sak koi daannawk, zaehhoihhaih daannawk hoi lokpaekhaihnawk to acoehaih hoi sah oh; kalah sithawnawk to bok o hmah.
Ó yẹ kí ẹ̀yin kí ó máa kíyèsi ara yín gidigidi láti pa ìlànà àti àṣẹ, àti òfin tí ó kọ fún un yín mọ́. Ẹ má ṣe sin ọlọ́run mìíràn.
38 Kai hoiah sak ih lokmaihaih to pahnet o hmah loe, kalah sithawnawk to bok o hmah.
Ẹ má ṣe gbàgbé májẹ̀mú tí mo ti ṣe pẹ̀lú yín mọ́ àti kí ẹ má sin ọlọ́run mìíràn.
39 Na Angraeng Sithaw khue to bok oh; to tiah ni anih mah na misa ban thung hoiah nangcae to pahlong tih, tiah lokpaekhaih to oh.
Kúkú sin Olúwa Ọlọ́run rẹ; Òun ni ẹni náà tí yóò gbà yín kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá a yín.”
40 Toe nihcae mah tahngai pae o ai moe, canghnii ah a sak o ih hmuen to pazui o toengtoeng vop.
Wọn kò ní gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni, wọ́n sì ń ṣe iṣẹ́ wọ́n ti àtijọ́.
41 Hae kaminawk loe angmacae hoi a caanawk ih caa patoeng khoek to, Angraeng to bok o, toe krangnawk doeh bok o toengtoeng vop; ampanawk mah sak o ih hmuen baktih toengah vaihni ni khoek to a sak o vop.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn wọn sin Olúwa, wọ́n sì ń sin òrìṣà wọn. Títí di ọjọ́ òní ọmọ wọn àti àwọn ọmọ ọmọ wọn sì ń ṣe bí àwọn baba wọn ti ń ṣe.

< 2 Siangpahrang 17 >