< 1 Samuel 21 >
1 David loe Nob vangpui ah kaom qaima Ahimelek khaeah caeh; Ahimelek mah David to hnuk naah zit; to pongah anih khaeah, Tikhoe minawk hoi angzo ai ah, nangmabueng nang zoh loe? tiah a naa.
Dafidi sì wá sí Nobu sọ́dọ̀ Ahimeleki àlùfáà, Ahimeleki sì bẹ̀rù láti pàdé Dafidi, ó sì wí fún un pé, “Èéha ti rí tí o fi ṣe ìwọ nìkan, àti tí kò sì sí ọkùnrin kan tí ó pẹ̀lú rẹ?”
2 David mah qaima Ahimelek khaeah, Siangpahrang mah hmuen maeto sak hanah ang paek; anih mah kai khaeah, Toksak hanih kang patoeh han, kang thuih ih lok hae mi mah doeh panoek hmah nasoe, tiah ang naa. Ka tamnanawk to ih ahmuen to baktih ahmuen ah angcu o hanah ka patoeh boeh.
Dafidi sì wí fún Ahimeleki àlùfáà pé, “Ọba pàṣẹ iṣẹ́ kan fún mi, ó sì wí fún mi pé, ‘Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ìdí iṣẹ́ náà ti mo rán ọ, àti èyí tí èmi ti pàṣẹ fún ọ.’ Èmi sì yan àwọn ìránṣẹ́ mi sí ibí báyìí.
3 Vaihi na ban ah timaw na tawnh? Na tawnh ih takaw kae pangato maw, to tih ai boeh loe na tawnh ih kawbaktih hmuen doeh na paek ah, tiah a naa.
Ǹjẹ́ kín ni ó wà ní ọwọ́ rẹ̀? Fún mi ni ìṣù àkàrà márùn-ún tàbí ohunkóhun tí o bá rí.”
4 Toe qaima mah David khaeah, Takaw rumram loe ka tawn ai, toe thendoeng loe nongpata khaeah caeh ai moe, ciimcai ah om nahaeloe, takaw ciim loe ka tawnh, tiah a naa.
Àlùfáà náà sí dá Dafidi lóhùn ó sì wí pé, “Kò sí àkàrà mìíràn lọ́wọ́ mi bí kò ṣe àkàrà mímọ́. Kìkì pé bi àwọn ọmọkùnrin bá ti pa ara wọn mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin!”
5 David mah qaima khaeah, Kholong ka caeh pacoeng hoi vaihni ni thumto karoek to, kawbaktih nongpata hoiah doeh kang kom ai; thendoeng ih hmuen loe ciimcai bae; takaw doeh kami boih mah caak ih takaw baktiah ni oh; vaihniah ni takaw kangtha to suek o vop, tiah a naa.
Dafidi sì dá àlùfáà náà lóhùn, ó sì wí fún un pé, “Nítòótọ́ ni a tí ń pa ara wá mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin láti ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta wá, tí èmí ti jáde. Gbogbo nǹkan àwọn ọmọkùnrin náà ni ó mọ́, àti àkàrà náà sì wá dàbí àkàrà mìíràn, pàápàá nígbà tí ó jẹ́ pé òmíràn wà tí a yà sí mímọ́ lónìí nínú ohun èlò náà!”
6 Caboi nuiah suek ih takaw ai ah loe, takaw kalah om ai boeh pongah, caboi nuiah suek ih takaw kangquem to takhoe moe, azuengah kangtha suek ih takaw, Angraeng hmaa ih kaciim takaw kabae to qaima mah lak anih hanah paek.
Bẹ́ẹ̀ ni àlùfáà náà sì fi àkàrà mímọ́ fún un; nítorí tí kò sí àkàrà mìíràn níbẹ̀ bí kò ṣe àkàrà ìfihàn tí a ti kó kúrò níwájú Olúwa, láti fi àkàrà gbígbóná síbẹ̀ ní ọjọ́ tí a kó o kúrò.
7 To na niah Saul ih tamna maeto to ahmuen ah oh toeng, anih loe Angraeng hmaa ah toksak; anih loe Edom kami ah oh, anih to Dog, tiah kawk o, anih loe Saul ih tuu toepkung ah oh.
Ọkùnrin kan nínú àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì ń bẹ níbẹ̀ lọ́jọ́ náà, tí a tí dádúró síwájú Olúwa; orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Doegi, ará Edomu olórí nínú àwọn darandaran Saulu.
8 David mah Ahimelek khaeah, Tayae, to tih ai boeh loe sumsen na tawn ai maw? Siangpahrang ih hmuen to karangah sak han oh pongah, kaimah ih sumsen hoiah palaanawk to ka sin ai, tiah a naa.
Dafidi sì tún wí fún Ahimeleki pé, “Kò sí ọ̀kọ̀ tàbí idà lọ́wọ́ rẹ níhìn-ín? Nítorí tí èmi kò mú idà mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mú nǹkan ìjà mi lọ́wọ́, nítorí pé iṣẹ́ ọba náà jẹ́ iṣẹ́ ìkánjú.”
9 Qaima mah, Nang mah Elah azawn ah hum ih Philistin acaeng Goliath ih sumsen loe hae ah oh; kahni hoi ayaw hmoek moe, khukbuen suekhaih ahnuk bangah oh bae; na koeh nahaeloe la khae, to hmuen khue ai ah loe kalah sumsen om ai, tiah a naa. David mah, To baktih hmuen loe naa ah doeh om ai, kai han na paek ah, tiah a naa.
Àlùfáà náà sì wí pé, “Idà Goliati ará Filistini tí ó pa ní àfonífojì Ela ní ń bẹ, wò ó, a fi aṣọ kan wé e lẹ́yìn efodu; bí ìwọ yóò bá mú èyí, mú un; kò sì sí òmíràn níhìn-ín mọ́ bí kò ṣe ọ̀kan náà.” Dafidi sì wí pé, “Kò sí èyí tí ó dàbí rẹ̀ fún mi.”
10 David mah Saul to zit pongah to na niah cawnh moe, Gath siangpahrang Akhish khaeah caeh.
Dafidi sì dìde, o sì sá ni ọjọ́ náà níwájú Saulu, ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọba Gati.
11 Toe Akhish ih tamnanawk mah anih khaeah, Hae David loe Israel siangpahrang na ai maw? Saul mah sangto hum moe, David mah sang hato hum, tiah hnawhaih hoi laasak o thuih ih kami na ai maw? tiah a naa o.
Àwọn ìránṣẹ́ Akiṣi sì wí fún un pé, “Èyí ha kọ́ ní Dafidi ọba ilẹ̀ náà? Ǹjẹ́ wọn kò ha ti dárin ti wọ́n sì gbe orin nítorí rẹ̀, tí wọ́n sì jó pé, “‘Saulu pa ẹgbẹ̀rún tirẹ̀. Dafidi sì pa ẹgbàárùn-ún tirẹ̀’?”
12 To lok to David mah palung thung hoi poek naah, Gath siangpahrang Akhish to paroeai zit.
Dafidi sì pa ọ̀rọ̀ wọ̀nyí í mọ́ ni ọkàn rẹ̀, ó sì bẹ̀rù Akiṣi ọba Gati gidigidi.
13 To pongah nihcae hmaa ah kamthu baktiah angsak pae moe, nihcae khaeah kamthu baktiah oh pae; a toektaboe mui pongah tamtuih to longsak moe, khongkha pongah angmathaih to tarik.
Òun sì pa ìṣe rẹ̀ dà níwájú wọn, ó sì sọ ara rẹ̀ di aṣiwèrè ní ọwọ́ wọn, ó sì ń fi ọwọ́ rẹ̀ ha ìlẹ̀kùn ojú ọ̀nà, ó sì ń wá itọ́ sí irùngbọ̀n rẹ̀.
14 Akhish mah a tamnanawk khaeah, khen oh, kamthu kami ho na hnu o ai maw, tih hanah kai khaeah nang hoih o loe?
Nígbà náà ni Akiṣi wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Wó o, nítorí kín ni ẹ̀yin ṣe mú un tọ̀ mí wá.
15 Kai mah kamthu kami patoh han koeh, tiah na poek o pong maw kai khaeah kamthu hae nang hoih o? Hae baktih kami hae ka imthung ah akun han oh maw? tiah a naa.
Mo ha ni un fi aṣiwèrè ṣe? Tí ẹ̀yin fi mú èyí tọ̀ mí wá láti hu ìwà aṣiwèrè níwájú mi? Eléyìí yóò ha wọ inú ilé mi?”