< Luhka 22 >
1 Nghngen am bawi khaia buhpawhnaka pawi; lätnakpawi ami ti ng'et lawki.
Àjọ ọdún àìwúkàrà tí à ń pè ní Ìrékọjá sì kù fẹ́ẹ́rẹ́.
2 Ktaiyü ngvai he la thum ksing he naw ami mkhyühnak vaia lam sui tekie khyang he jah kyüh u lü anghmüa hnim khai hea ami bü.
Àti àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀wé ń wá ọ̀nà tí wọn ìbá gbà pa á; nítorí tí wọn ń bẹ̀rù àwọn ènìyàn.
3 Acunüng, xaleinghngih üngka Judah Iskarot ami tia k'uma khawyam lut se,
Satani sì wọ inú Judasi, tí à ń pè ní Iskariotu, ọ̀kan nínú àwọn méjìlá.
4 ktaiyü ngvai he la Temple ngängki hea veia cit lü, Jesuh ikba man vai tia a jah va cengpüi.
Ó sì mú ọ̀nà rẹ̀ pọ̀n, ó lọ láti bá àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olórí ẹ̀ṣọ́ gbèrò pọ̀, bí òun yóò tí fi í lé wọn lọ́wọ́.
5 Amimi naw jekyai u lü ngui ami pet vaia ami mkhyäp.
Wọ́n sì yọ̀, wọ́n sì bá a dá májẹ̀mú láti fún un ní owó.
6 Acunüng Judah Iskarot naw ngaisim lü khyang he am ami ve üng a jah mansak vaia lam suiki.
Ó sì gbà; ó sì ń wá àkókò tí ó wọ̀, láti fi í lé wọn lọ́wọ́ láìsí ariwo.
7 Acunüng nghngen am bawikia buhpawh mhmüp, lätnakpawi vaia toca hnimnaka mhmüp pha law se,
Ọjọ́ àìwúkàrà pé, nígbà tí wọ́n ní láti pa ọ̀dọ́-àgùntàn ìrékọjá fún ìrúbọ.
8 Jesuh naw, Pita la Johana veia, Lätnakpawi buh mi einak vai va pawh ni,” ti lü a jah tüih.
Ó sì rán Peteru àti Johanu, wí pé, “Ẹ lọ pèsè ìrékọjá fún wa, kí àwa ó jẹ.”
9 Anini naw, “Hawia pawh vai ni na ngjak hlü?” ani ti.
Wọ́n sì wí fún un pé, “Níbo ni ìwọ ń fẹ́ kí á pèsè sílẹ̀?”
10 Jesuh naw, Mlüh the nani va luh üng, kpami k'am üng tui kawtki naw ning jah na khyum khai ni, a luhnaka ima nani läk vai.
Ó sì wí fún wọn pé, “Kíyèsi i, nígbà tí ẹ̀yin bá ń wọ ìlú lọ, ọkùnrin kan tí ó ru ìkòkò omi yóò pàdé yín, ẹ bá a lọ sí ilé tí ó bá wọ̀,
11 “Imaha veia, ‘Saja naw, ka xüisaw he am lätnakpawi buh kami einak vaia khinim hawia ni? ti ve,’ nani ti vai.
kí ẹ sì wí fún baálé ilé náà pé, ‘Olùkọ́ wí fún ọ pé, níbo ni gbàngàn àpèjẹ náà gbé wà, níbi tí èmi ó gbé jẹ ìrékọjá pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi?’
12 “Ani naw khin im angsawng kcang, ahmäi am kümki im khan ning jah mhmuh khai; acunüng va ngtüna ni,” a ti.
Òun ó sì fi gbàngàn ńlá kan lókè ilé hàn yín, tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́, níbẹ̀ ni kí ẹ̀yin pèsè sílẹ̀.”
13 A jah mtheha kba cit ni lü ani va hmuh, acuia lätnakpawi buh ani va ngtünak.
Wọ́n sì lọ wọ́n sì bá a gẹ́gẹ́ bí ó tí sọ fún wọn, wọ́n sì pèsè ìrékọjá sílẹ̀.
14 Acunüng Jesuh la a ngsä he eikbe üng atänga ei hmaihki he.
Nígbà tí àkókò sì tó, ó jókòó àti àwọn aposteli pẹ̀lú rẹ̀.
15 Jesuh naw, “Am ka thih hlan üng hina lätnakpawi buh atänga ka ning jah eipüi vai ka ngja hlü leng lengki,
Ó sì wí fún wọn pé, “Tinútinú ni èmi fẹ́ fi bá yín jẹ ìrékọjá yìí, kí èmi tó jìyà.
16 “Ka ning jah mthehki, Pamhnama khawa hin akcanga am a kya hlana küt üng am ei hlü be ti veng,” a ti.
Nítorí mo wí fún yín, Èmi kì yóò jẹ nínú rẹ̀ mọ́, títí a ó fi mú un ṣẹ ní ìjọba Ọlọ́run.”
17 Acunüng khawt lo lü Pamhnama veia jekyainak ngthu pyen lü, “Hin hin lo u lü, ng’yet ua;
Ó sì gba ago, nígbà tí ó sì ti dúpẹ́, ó wí pé, “Gba èyí, kí ẹ sì pín in láàrín ara yín.
18 ka ning jah mthehki, atuh üng tün lü Pamhnama khaw am a pha law cäpa capyitui am ka aw be ti khai,” a ti.
Nítorí mo wí fún yín, Èmi kì yóò mu nínú èso àjàrà mọ́, títí ìjọba Ọlọ́run yóò fi dé.”
19 Acunüng muk lo lü Pamhnama veia jekyainaka ngthu a pyen law päng üng, boki naw jah pe lü, “Hin hin nami hama peta ka mtisa ni, nami na sümnak vaia pawh ua” a ti.
Ó sì mú àkàrà, nígbà tí ó sì ti dúpẹ́ ó bù ú, ó sì fi fún wọn, ó wí pé, “Èyí ni ara mí tí a fi fún yín, ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi.”
20 Müei a ei law päng üng, acunkba bäa khawt lo lü, “Hina khawt hin ka thisen, nami hama ngsawikia Pamhnama ngthumkhän kthaia kyaki.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó sì mú ago wáìnì, ó wí pé, “Ago yìí ni májẹ̀mú tuntun nínú ẹ̀jẹ̀ mi, tí a ta sílẹ̀ fún yín.
21 “Acunakyasepi, na mansak khaia khyang cun hina eikbea khana kani awm hmaihki ni!
Ṣùgbọ́n ẹ kíyèsi i, ọwọ́ ẹni tí yóò fi mí hàn wà pẹ̀lú mi lórí tábìlì.
22 Khyanga Capa hin Mhnama mkhyaha kba cit khai, cunsepi jah mansak khaia cengkia khyang ta a jo se ve,” a ti.
Ọmọ Ènìyàn ń lọ nítòótọ́ bí a tí pinnu rẹ̀, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ọkùnrin náà nípasẹ̀ ẹni tí a gbé ti fi í hàn.”
23 Acunüng axüisaw he amimät, “Acukba kya khai ta u ni?” tia, ngthäh kyuki he.
Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí béèrè láàrín ara wọn, ta ni nínú wọn tí yóò ṣe nǹkan yìí.
24 Axüisaw he amimät, u ni akyäp säih tia ngcuh u se,
Ìjà kan sì ń bẹ láàrín wọn, ní ti ẹni tí a kà sí olórí nínú wọn.
25 Jesuh naw, “Am jumeiki hea sangpuxang he cun khyang hea khana aktäa bawi khawiki he, khaw uki he naw ‘Khyang hea püi he’ tia ami jah khü jawngnaki he.
Ó sì wí fún wọn pé, “Àwọn ọba aláìkọlà a máa fẹlá lórí wọn, a sì máa pe àwọn aláṣẹ wọn ní olóore.
26 “Cunsepi, nangmi ta acunkba ä awm u, nangmi üng kyäp säihki cen jaw säihkia kba, mkhawng säiki cen m'yaa kba ve se.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kì yóò rí bẹ́ẹ̀; ṣùgbọ́n ẹni tí ó ba pọ̀jù nínú yín kí ó jẹ́ bí ẹni tí o kéré ju àbúrò; ẹni tí ó sì ṣe olórí, bí ẹni tí ń ṣe ìránṣẹ́.
27 “U ni a kyäp säih? Ngaw lü buh eiki japaw a kyäp säih? Buh khünki aw a kyäp säih? Ngaw lü buh eikia am kya aih se? Cunsepi, kei ta nami veia ning jah khüihkia kba ka awmki.
Nítorí ta ni ó pọ̀jù, ẹni tí ó jókòó tí oúnjẹ, tàbí ẹni tí ó ń ṣe ìránṣẹ́. Ẹni tí ó jókòó ti oúnjẹ kọ́ bí? Ṣùgbọ́n èmi ń bẹ láàrín yín bí ẹni tí ń ṣe ìránṣẹ́.
28 “Khuikha lü ka awm üng nami na awmpüiki.
Ẹ̀yin ni àwọn tí ó ti dúró tì mí nínú ìdánwò mi.
29 “Ka Pa naw uknak thei a na peta kba kei naw pi ka ning jah pe khai.
Mo sì yan ìjọba fún yín, gẹ́gẹ́ bí Baba mi ti yàn fún mi.
30 Nangmi cun ka eikbe üng ngaw u lü ka khawa nami ei aw hnga khai. Bawingawhnak he üng ngaw u lü Isarel pakhui xaleinghngih he ngthu nami jah mkhyah khai.
Kí ẹ̀yin lè máa jẹ, kí ẹ̀yin sì lè máa mu lórí tábìlì mi ní ìjọba mi, kí ẹ̀yin lè jókòó lórí ìtẹ́, àti kí ẹ̀yin lè máa ṣe ìdájọ́ fún àwọn ẹ̀yà Israẹli méjìlá.”
31 “Sihmon, Sihmon, Ngaia! lomah naw angsi kphya am a mkhyaha kba, khawyam naw a ning hlawhlepnak vaia akhawn yah päng ve,
Olúwa sì wí pé, “Simoni, Simoni, wò ó, Satani fẹ́ láti gbà ọ́, kí ó lè kù ọ́ bí alikama.
32 “Cunsepi, na jumnak am a khyühnak vaia, ka ning ktaiyü peki ni; ka veia na nghlat law be üng, na bena he jah khängsak kaw pi,” a ti.
Ṣùgbọ́n mo ti gbàdúrà fún ọ, kí ìgbàgbọ́ rẹ má ṣe yẹ̀; àti ìwọ nígbà tí ìwọ bá sì padà bọ̀ sípò, mú àwọn arákùnrin rẹ lọ́kàn le.”
33 Pita naw, “Bawipa aw, na veia ta thawngim la thihnak üng pi ka ceh vai ling veng,” a ti.
Ó sì wí fún un pé, “Olúwa, mo múra tán láti bá ọ lọ sínú túbú, àti sí ikú.”
34 Jesuh naw, “Pita aw, ka ning mthehki, tuhngawi ai am khawng pha se, ‘Ani am ksing nawng’ ti lü kthum vei na ngcim khai,” a ti.
Ó sì wí pé, “Mo wí fún ọ, Peteru, àkùkọ kì yóò kọ lónìí tí ìwọ ó fi sẹ́ mi lẹ́ẹ̀mẹ́ta pé, ìwọ kò mọ̀ mí.”
35 Jesuh naw, “Ajana, nguiip, ngja, khawdawk, am nami cehei khaia ka ning jah tüih üng, nami hlü ei i awmki aw?” ti se amimi naw, “I am hlü naw,” ami ti.
Ó sì wí fún wọn pé, “Nígbà tí mo rán yín lọ láìní àpò-owó, àti àpò, àti bàtà, ọ̀dá ohun kan dá yín bí?” Wọ́n sì wí pé, “Rárá!”
36 Acunüng Jesuh naw, “Atuh ta aupi nguiip la ngja taki naw cehei se; kcim am taki naw a suisak jawi lü kheihei se.
Nígbà náà ni ó wí fún wọn pé, “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹni tí ó bá ní àpò-owó kí ó mú un, àti àpò pẹ̀lú; ẹni tí kò bá sì ní idà, kí ó ta aṣọ rẹ̀, kí ó sì fi ra ọ̀kan.
37 “Ka ning jah mthehki, ‘Ani cun khyangka he mah maha ami täh si’ tia, ng’yuki ka khana kümkawi law khaia kyaki; keia mawngma ngthu he kümkawi law bäih ve u,” a ti.
Nítorí mo wí fún yín pé, ‘Èyí tí a ti kọ̀wé rẹ̀ kò lè ṣe kí ó má ṣẹ lára mi, a sì kà á mọ́ àwọn arúfin.’ Nítorí àwọn ohun wọ̀nyí nípa ti èmi yóò ní ìmúṣẹ.” tí a sì kà á mọ́ àwọn alárékọjá.
38 Amimi naw, “Bawipa aw, tenga! kcim nghngih awmki,” ti u se, Jesuh naw, “Khäk ve” a ti.
Wọ́n sì wí pé, “Olúwa, sá wò ó, idà méjì ń bẹ níhìn-ín yìí!” Ó sì wí fún wọn pé, “Ó tó.”
39 Jesuh cun a thum khawia kba, Olip mcunga ktawih se, axüisaw he naw ami läk hnga.
Ó sì jáde, ó sì lọ bí ìṣe rẹ̀ sí òkè olifi, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
40 Ahmün a va pha üng, “Hlawhlepnaknak üngka naw nami lätnak vaia, ktaiyü ua,” a ti.
Nígbà tí ó wà níbẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ máa gbàdúrà, kí ẹ̀yin má ṣe bọ́ sínú ìdẹwò.”
41 Lung vawi lü aphanak cäpa va cit lü; a mkhuk ngdäng lü,
Ó sì fi wọ́n sílẹ̀ níwọ̀n ìsọ-òkò kan, ó sì kúnlẹ̀ ó sì ń gbàdúrà.
42 “Ka pa aw, na hlüei üng ta hina khuikhanak khawt ka vei üngka naw loin kawpi, cunsepi keia ngjak hlüa am kya lü, namäta ngjak hlüa kya se,” ti lü ktaiyüki.
Wí pé, “Baba, bí ìwọ bá fẹ́, mu ago yìí kúrò lọ́dọ́ mi: ṣùgbọ́n ìfẹ́ ti èmi kọ́, bí kò ṣe tìrẹ ni kí à ṣe.”
43 Khankhaw üngka khankhawngsä mat Jesuh kthayüi pe khaia ngdang lawki.
Angẹli kan sì yọ sí i láti ọ̀run wá, ó ń gbà á ní ìyànjú.
44 Aktä leng lenga khuikha lü, kthana kcang lü, ktaiyü se a ngkhyantui thisena mäiha mdek üng ngsawi lawki.
Bí ó sì ti wà nínú gbígbóná ara ó ń gbàdúrà sí i kíkankíkan; òógùn rẹ̀ sì dàbí ìró ẹ̀jẹ̀ ńlá, ó ń kán sílẹ̀.
45 A ktaiyü law päng üng tho law lü axüisaw hea veia cit teki ami mlunga nata phäha a na ip u se a jah hmuh.
Nígbà tí ó sì dìde kúrò ní ibi àdúrà, tí ó sì tọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá, ó bá wọn, wọ́n ń sùn nítorí ìbànújẹ́ ti mu kí ó rẹ̀ wọ́n.
46 Jesuh naw, “Ise nami ipki ni? Hlawhlepnak üngka naw nami lätnak vaia tho law u lü ktaiyü ua,” a ti.
Ó sì wí fún wọn pé, “Kí ni ẹ̀ yin ń sùn sí? Ẹ dìde, ẹ máa gbàdúrà, kí ẹ̀yin má ṣe bọ́ sínú ìdẹwò.”
47 Acukba a na ngthuhei k’um üng, xaleinghngih he üngka Judah ami ti naw jah xüi lü, khyang he jah lawpüiki naw, Jesuh mhnam khai bü lü a pan law.
Bí ó sì ti ń sọ lọ́wọ́, kíyèsi i, ọ̀pọ̀ ènìyàn, àti ẹni tí a ń pè ní Judasi, ọ̀kan nínú àwọn méjìlá, ó ṣáájú wọn, ó súnmọ́ Jesu láti fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
48 Jesuh naw, “Judah aw khyanga Capa hin mhnam khaia bü lü na jah man sak khai aw?” a ti.
Jesu sì wí fún un pé, “Judasi, ìwọ yóò ha fi ìfẹnukonu fi Ọmọ Ènìyàn hàn?”
49 Acunüng axüisaw he a peia awmki he naw, ia akya law vai sim u lü, “Bawipa aw, kcim am kami jah pawh khai aw?” ami ti.
Nígbà tí àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ ń wo bí nǹkan yóò ti jásí, wọ́n bi í pé, “Olúwa kí àwa fi idà sá wọn?”
50 Acunüng mat naw ktaiyü ngvai säiha m'yaa nghngakawi kpat lam a ksawm pat.
Ọ̀kan nínú wọn sì fi idà ṣá ọmọ ọ̀dọ̀ olórí àlùfáà, ó sì gé etí ọ̀tún rẹ̀ sọnù.
51 Jesuh naw, “Khäk ve,” ti lü a nghngakawi hnet se daw beki.
Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn ó wí pé, “Ko gbọdọ̀ ṣe èyí mọ.” Ó sì fi ọwọ́ tọ́ ọ ní etí, ó sì wò ó sàn.
52 Jesuh naw a veia lawki hea ktaiyü ngvai he, Temple üng ngvai he la, axüngvai he üng, “Mthikcim la kpaihmäng jah kawtei u lü m'yukei man khai hea kba nami na lawsiki aw?
Jesu wí fún àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn olórí ẹ̀ṣọ́ tẹmpili, àti àwọn alàgbà, tí wọ́n jáde tọ̀ ọ́ wá pé, “Ẹ̀yin ha jáde wá pẹ̀lú idà àti ọ̀kọ̀ bí ẹni tọ ọlọ́ṣà wá?
53 Temple üng amhmüp tä nami veia ve ni se am nami na manki. Cunsepi atuh hin nami kcüna kya lü nghmüpa khyaihnaka kya ve,” a ti.
Nígbà tí èmi wà pẹ̀lú yín lójoojúmọ́ ní tẹmpili, ẹ̀yin kò na ọwọ́ mú mi, ṣùgbọ́n àkókò tiyín ni èyí, àti agbára òkùnkùn n jẹ ọba.”
54 Jesuh kpang u lü cehpüiki he naw ktaiyü ngvaia ima ami luhpüi. Acunüng, Pita naw athuknak üngka naw a läk hnga.
Wọ́n sì gbá a mú, wọ́n sì fà á lọ, wọ́n sì mú un wá sí ilé olórí àlùfáà. Ṣùgbọ́n Peteru tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ní òkèrè.
55 Imngvawng mkawt nglung üng mei awm u lü ngaw u se Pita ami ksunga va ngaw hngaki.
Nígbà tí wọ́n sì ti dáná láàrín àgbàlá, tí wọ́n sì jókòó pọ̀, Peteru jókòó láàrín wọn.
56 Meikdäi peia ngaw se nglaca mat naw hmu lü a hmai üng teng kyetki naw, “Hina khyang pi Jesuh am awm khawiki xawi ni,” a ti.
Ọmọbìnrin kan sì rí i bí ó ti jókòó níbi ìmọ́lẹ̀ iná náà, ó sì tẹjúmọ́ ọn, ó ní, “Eléyìí náà wà pẹ̀lú rẹ̀.”
57 Pita naw, “Nghnumi aw, ani am ksing nawng,” ti lü, ngcimki.
Ṣùgbọ́n, ó wí pé, “Obìnrin yìí, èmi kò mọ̀ ọ́n.”
58 Acunkäna, khyang kce mat naw hmu lü, “Nang pi acun he üngka mat ni,” ti se, Pita naw, “Khyang aw, am kya nawng,” a ti.
Kò pẹ́ lẹ́yìn náà ẹlòmíràn sì rí i, ó ní, “Ìwọ pẹ̀lú wà nínú wọn.” Ṣùgbọ́n Peteru wí pé, “Ọkùnrin yìí, èmi kọ́.”
59 Acunüng naji mat ngsawk se khyang mat naw, “Hina khyang pi Jesuha hlawnga awm khawiki ni; Kalile khaw khyanga kya ye se,” a ti.
Ó sì tó bí i wákàtí kan síbẹ̀ ẹlòmíràn tẹnumọ́ ọn, wí pé, “Nítòótọ́ eléyìí náà wà pẹ̀lú rẹ̀: nítorí ará Galili ní í ṣe.”
60 Acunüng, Pita naw, “Khyang aw na pyen am ksing nawng,” a ti. A na ngcim k’um üng angxita ai khawng law ktäihki.
Ṣùgbọ́n Peteru wí pé, “Ọkùnrin yìí, èmi kò mọ ohun tí ìwọ ń wí!” Lójúkan náà, bí ó tí ń wí lẹ́nu, àkùkọ kọ!
61 Jesuh naw nghlat lü Pita a teng. Pita naw Jesuha pyen, “Tuhngawi, ai am khawng pha se kthum vei, ‘Am ksing nawng’ ti lü na ngcim khai,” a ti cun süm law beki.
Olúwa sì yípadà, ó wo Peteru. Peteru sì rántí ọ̀rọ̀ Olúwa, bí ó ti wí fún un pé, “Kí àkùkọ tó kọ, ìwọ ó sẹ́ mi lẹ́ẹ̀mẹ́ta.”
62 Acunüng, Pita kpunga cit lü aktäa kyapki.
Peteru sì bọ́ sí òde, ó sọkún kíkorò.
63 Jesuh ngängki he naw yaiha pawh u lü ami kpaih.
Ó sì ṣe, àwọn ọkùnrin tí wọ́n mú Jesu, sì fi í ṣe ẹlẹ́yà, wọ́n lù ú.
64 A mik bu u lü, “U naw ning kpaiki, pyena?” tia ami kthäh.
Nígbà tí wọ́n sì dì í ní ojú, wọ́n lù ú níwájú, wọ́n ń bi í pé, “Sọtẹ́lẹ̀! Ta ni ó lù ọ́?”
65 Ngthu khawjah am kse na u lü ami jüih.
Wọ́n sì sọ ọ̀pọ̀ ohun búburú mìíràn sí i, láti fi ṣe ẹlẹ́yà.
66 Khaw a thaih law la khyang ngvai he, ktaiyü ngvai he la, thum ksing he avang ngcun lawki he naw ami Kawngcia cehpüi u lü,
Nígbà tí ilẹ̀ sì mọ́, ìjọ àwọn alàgbà àwọn ènìyàn péjọpọ̀, àti àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀wé, wọ́n sì fà á lọ sí àjọ wọn, wọ́n ń wí pé,
67 “Mesijaha na kya kcang üng jah mtheh law,” ami ti. Acunüng, Jesuh naw, “Ning jah mtheh ni se pi am nami na kcang na khai;
“Bí ìwọ bá jẹ́ Kristi náà? Sọ fún wa!” Ó sì wí fún wọn pé, “Bí mo bá wí fún yín, ẹ̀yin kì yóò gbàgbọ́,
68 ning jah kthäh ni se pi am nami na msang khai.
bí mo bá sì bi yín léèrè pẹ̀lú, ẹ̀yin kì yóò dá mi lóhùn.
69 Cunsepi, atuh üng tün lü khyanga Capa cun hlüngtai kyäpsawkia Pamhnama kpat da ngaw khai,” a ti.
Ṣùgbọ́n láti ìsinsin yìí lọ ni Ọmọ Ènìyàn yóò jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún agbára Ọlọ́run.”
70 Acunüng ami van naw, “Nang hin Pamhnama Capa kya aih lü?” ami ti. Acunüng Jesuh naw, “Ä, nami pyena kba kya veng,” a ti.
Gbogbo wọn sì wí pé, “Ìwọ ha ṣe Ọmọ Ọlọ́run bí?” Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin wí pé, èmi ni.”
71 Amimi naw, “Ia saksi akce hlü be se ni? Amäta mka ye üng mi ngja ve,” ami ti.
Wọ́n sì wí pé, “Ẹ̀rí wo ni àwa tún ń fẹ́ àwa tìkára wa sá à ti gbọ́ lẹ́nu rẹ̀!”