< Zacarias 10 >

1 Pangayog ulan gikan kang Yahweh sa panahon sa tingpamulak—si Yahweh nga maoy nagbuhat sa mga dalugdog—ug naghatag siyag ulan sa matag-usa ug sa tanang pananom sa kaumahan.
Ẹ béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa; Olúwa tí o dá mọ̀nàmọ́ná, tí ó sì fi ọ̀pọ̀ òjò fún ènìyàn, fún olúkúlùkù koríko ní pápá.
2 Tungod kay nagsultig bakak ang mga diosdios sa panimalay; bakak ang panan-awon sa mga mini nga mananagna; nagsulti sila ug malimbongon nga mga damgo ug naghatag ug haw-ang nga paghupay, busa naglatagaw sila sama sa karnero ug nag-antos tungod kay wala silay magbalantay.
Nítorí àwọn òrìṣà tí sọ̀rọ̀ asán, àwọn aláfọ̀ṣẹ sì tí rí èké, wọn sì tí rọ àlá èké; wọ́n ń tu ni nínú lásán, nítorí náà àwọn ènìyàn náà ṣáko lọ bí àgùntàn, a ṣẹ wọn níṣẹ̀ẹ́, nítorí Olùṣọ́-àgùntàn kò sí.
3 Misilaob ang akong kasuko batok sa mga magbalantay sa karnero; pagasilotan ko kadtong mga laking kanding—nga mao ang mga pangulo. Tabangan usab ni Yahweh nga labawng makagagahom ang iyang panon, ang balay sa Juda, ug himoon silang daw iyang kabayo diha sa panaggubat!
“Ìbínú mi ru sí àwọn darandaran, èmi o sì jẹ àwọn olórí ní yà nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti bẹ agbo rẹ̀, ilé Juda wò, yóò sì fi wọn ṣe ẹṣin rẹ̀ dáradára ní ogun.
4 Magagikan kanila ang upat ka patukoranan; magagikan kanila ang ugsok sa tolda; magagikan kanila ang pana sa gubat; magagikan kanila ang tanang pangulo.
Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni èèkàn àgọ́ tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrún ogun tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni àwọn akóniṣiṣẹ́ gbogbo tí wá.
5 Mahisama sila sa mga manggugubat nga motamaktamak sa ilang mga kaaway didto sa lapok nga kadalanan panahon sa gubat; makiggubat sila, tungod kay nag-uban kanila si Yahweh, ug pakaulawan nila kadtong mga nagsakay sa mga kabayo nga panggubat.
Gbogbo wọn yóò sì dàbí ọkùnrin alágbára ni ogun tí ń tẹ àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀ ní ìgboro, wọn ó sì jagun, nítorí Olúwa wà pẹ̀lú wọn, wọn ó sì dààmú àwọn tí ń gun ẹṣin.
6 Lig-onon ko ang balay sa Juda ug luwason ang balay ni Jose; tungod kay ipasig-uli ko sila ug magmanggiluluy-on diha kanila. Mahimo silang daw wala ko sila gisalikway, tungod kay ako si Yahweh nga ilang Dios, ug tubagon ko sila.
“Èmi o sì mú ilé Juda ní agbára, èmi o sì gba ilé Josẹfu là, èmi ó sì tún mú wọn padà nítorí mo tí ṣàánú fún wọn, ó sì dàbí ẹni pé èmi kò ì tì í ta wọ́n nù; nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi o sì gbọ́ tiwọn
7 Unya mahisama si Efraim sa manggugubat, ug maglipay ang ilang mga kasingkasing ingon nga adunay bino; makakita ang ilang mga anak ug magsadya. Maglipay ang ilang mga kasingkasing kanako!
Efraimu yóò sì ṣe bí alágbára, ọkàn wọn yóò sì yọ̀ bi ẹni pé nípa ọtí wáìnì: àní àwọn ọmọ wọn yóò rí í, wọn o sì yọ̀, inú wọn ó sì dùn nínú Olúwa.
8 Tawgon ko sila ug tapokon, tungod kay luwason ko sila, ug mahimo silang bantogan sama kaniadto!
Èmi ó kọ sí wọn, èmi ó sì ṣà wọ́n jọ; nítorí èmi tí rà wọ́n padà; wọn ó sì pọ̀ sí i gẹ́gẹ́ bí wọ́n tí ń pọ̀ sí í rí.
9 Gitanom ko sila taliwala sa mga katawhan, apan mahinumduman nila ako sa halayong nasod, busa mabuhi ug mamalik sila ug ang ilang mga anak.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo tú wọn káàkiri orílẹ̀-èdè: síbẹ̀ wọn ó sì rántí mi ni ilẹ̀ jíjìn; wọn ó sì gbé pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn, wọn ó sì tún padà.
10 Tungod kay ibalik ko sila gikan sa yuta sa Ehipto ug tigomon sila gikan sa Asiria. Pagadad-on ko sila ngadto sa yuta sa Gilead ug sa Lebanon hangtod nga wala na gayoy igong dapit alang kanila.
Èmi ó sì tún mú wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú, èmi ó sì ṣà wọn jọ kúrò ni ilẹ̀ Asiria. Èmi ó sì mú wọn wá sí ilẹ̀ Gileadi àti Lebanoni; a kì yóò sì rí ààyè fún wọn bí ó ti yẹ.
11 Motabok ako sa dagat sa ilang pag-antos; hampakon ko ang mga balod sa dagat ug paugahon ang tanang kinahiladman sa Nilo. Pagahugnoon ang kahalangdon sa Asiria, ug pagawagtangon ang sitro sa Ehipto gikan sa mga Ehiptohanon.
Wọn yóò sì la Òkun wàhálà já, yóò sì bori rírú omi nínú Òkun, gbogbo ibú odò ni yóò sì gbẹ, a ó sì rẹ ìgbéraga Asiria sílẹ̀, ọ̀pá aládé Ejibiti yóò sí lọ kúrò.
12 Lig-onon ko sila dinhi sa akong kaugalingon, ug molakaw sila sa akong ngalan— mao kini ang gipamulong ni Yahweh.
Èmi ó sì mú wọn ní agbára nínú Olúwa; wọn ó sì rìn sókè rìn sódò ni orúkọ rẹ̀,” ni Olúwa wí.

< Zacarias 10 >