< Job 40 >

1 Nagpadayon sa pagpakigsulti si Yahweh ngadto kang Job; miingon siya,
Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,
2 “Si bisan kinsa ba nga buot manaway mosulay sa pagbadlong sa Makagagahom? Siya nga makiglalis sa Dios, patubaga siya.”
“Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́? Ẹni tí ń bá Ọlọ́run wí jẹ́ kí ó dáhùn!”
3 Unya mitubag si Job kang Yahweh ug miingon,
Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,
4 “Tan-awa, dili ako mahinungdanon; busa unsaon ko man ikaw pagtubag? Ibutang ko ang akong kamot sa akong baba.
“Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.
5 Misulti ako sa makausa, ug dili na ako motubag; sa pagkatinuod, kaduha, apan dili na ako magpadayon pa.”
Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́; lẹ́ẹ̀kejì ni, èmi kò sì le ṣe é mọ́.”
6 Unya mitubag si Yahweh kang Job gikan sa bangis kaayo nga unos ug miingon,
Nígbà náà ní Olúwa dá Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká wá, ó sì wí pé,
7 “Karon, itaod ang imong bakos sama sa usa ka lalaki, tungod kay pangutan-on ko ikaw, ug kinahanglan nga tubagon mo ako.
“Di àmùrè gírí ní ẹgbẹ́ rẹ bí ọkùnrin, èmi ó bi ọ léèrè, kí ìwọ kí ó sì dá mi lóhùn.
8 Moingon ka ba gayod nga dili ako makataronganon? Hukman mo ba ako aron angkonon mo nga sakto ka?
“Ìwọ ha fẹ́ mú ìdájọ́ mi di asán? Ìwọ ó sì dá mi lẹ́bi, kí ìwọ lè ṣe olódodo.
9 May bukton ka ba sama sa Dios? Makapadalugdog ka ba sa imong tingog sama kaniya?
Ìwọ ni apá bí Ọlọ́run tàbí ìwọ lè fi ohùn sán àrá bí òun?
10 Karon, sul-obi ang imong kaugalingon sa himaya ug dungog; sul-obi ang imong kaugalingon sa kadungganan ug kahalangdon.
Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ní ọ̀ṣọ́, tí ó sì fi ògo àti títóbi ọ̀ṣọ́ bo ara ní aṣọ.
11 Ipakatag ang naghinubra nimong kasuko; tan-awa ang tanan nga garboso ug ipaubos siya.
Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde; kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ kí o sì rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
12 Tan-awa ang tanan nga mapasigarbohon ug ipaubos siya; tamaki ang daotang mga tawo kung diin sila nagbarog.
Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn kí o sì rẹ ẹ sílẹ̀ kí o sì tẹ ènìyàn búburú mọ́lẹ̀ ní ipò wọn.
13 Ilubong silang tanan ilalom sa yuta; bilanggoa ang ilang mga dagway sa tagong dapit.
Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀, kí o sì di ojú ìkọ̀kọ̀ wọn ní isà òkú.
14 Unya ilhon ko usab ikaw nga ang imong tuong kamot makaluwas kanimo.
Nígbà náà ní èmi ó yìn ọ́ pé, ọwọ́ ọ̀tún ara rẹ lè gbà ọ́ là.
15 Tan-awa karon ang behemot, nga hinimo usab nako sama sa paghimo ko kanimo; nagakaon siya ug sagbot sama sa torong baka.
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti, tí mo dá pẹ̀lú rẹ, òun a máa jẹ koríko bí ọ̀dá màlúù.
16 Tan-awa karon, ang iyang kusog anaa sa iyang hawakan; ang iyang gahom anaa sa mga unod sa iyang tiyan.
Wò o nísinsin yìí, agbára rẹ wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, àti ipa rẹ nínú ìṣàn ìkún rẹ.
17 Lihokon niya ang iyang ikog sama sa kahoy nga sedro; ang unod sa iyang paa nag-abot.
Òun a máa jù ìrù rẹ̀ bí i igi kedari, iṣan itan rẹ̀ dìjọ pọ̀.
18 Ang iyang mga bukog sama sa mga tubo nga tumbaga; ang iyang tiil sama sa mga babag nga puthaw.
Egungun rẹ̀ ní ògùṣọ̀ idẹ, Egungun rẹ̀ dàbí ọ̀pá irin.
19 Siya ang pangulo sa mga binuhat sa Dios. Ang Dios lamang, nga nagbuhat kaniya, ang makalupig kanila.
Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run; síbẹ̀ Ẹlẹ́dàá rẹ̀ fi idà rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
20 Kay ang kabungtoran naghatag kaniya ug pagkaon; ang mabangis nga mga mananap sa yuta nagduladula sa duol.
Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá ní i mu ohun jíjẹ fún un wá, níbi tí gbogbo ẹranko igbó máa ṣiré ní ẹ̀gbẹ́ ibẹ̀.
21 Naghigda siya ilalom sa bulak nga lirio diha sa landong sa kasagbotan ug diha sa lamakan.
Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì, lábẹ́ eèsún àti ẹrẹ̀.
22 Nagtabon kaniya ang landong sa bulak nga lirio; ang kahoy nga tambo diha sa gamay nga sapa naglibot kaniya.
Igi lótusì síji wọn bò o; igi arọrọ odò yí i káàkiri.
23 Tan-awa, kung magbaha ang kilid sa sapa, dili siya mangurog; masaligon siya, bisan kung ang Suba sa Jordan moabot hangtod sa iyang ilong.
Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun kò sálọ; ó wà láìléwu bí ó bá ṣe pé odò Jordani ti ṣàn lọ sí ẹnu rẹ̀.
24 Aduna bay makadakop kaniya gamit ang taga, o makatusok sa iyang ilong pinaagi sa lit-ag?
Ẹnìkan ha lè mú un ní ojú rẹ̀, tàbí dẹkùn fún tàbí a máa fi ọ̀kọ̀ gún imú rẹ̀?

< Job 40 >