< Hosea 5 >

1 Paminawa kini, mga pari! Hatagig pagtagad, panimalay sa Israel! Paminaw, panimalay sa hari! Tungod kay moabot ang paghukom batok kaninyong tanan. Nahimo kamong lit-ag ngadto sa Mizpa ug pukot nga gibukhad ngadto sa Tabor.
“Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yìn àlùfáà! Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ọmọ Israẹli! Ẹ gbọ́, ẹ̀yìn ilé ọba! Ìdájọ́ yìí kàn yín. Ẹ ti jẹ́ ẹ̀bìtì ní Mispa àwọ̀n ti a nà sílẹ̀ lórí Tabori.
2 Nagtindog ang mga masinupakon sa kinahiladman sa pagpamatay, apan silotan ko silang tanan.
Àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti gbilẹ̀ nínú ìpànìyàn gbogbo wọn ni èmi ó bá wí,
3 Nakaila ako kang Efraim, ug wala matago kanako ang Israel. Efraim, karon nahimo kang sama sa babaye nga nagbaligya ug dungog; nahugawan ang Israel.
mo mọ ohun gbogbo nípa Efraimu Israẹli kò sì pamọ́ fún mi Efraimu, ní báyìí ó ti ṣe àgbèrè Israẹli sì ti díbàjẹ́.
4 Dili sila tugotan sa ilang mga binuhatan nga mobalik sa Dios, tungod kay anaa kanila ang hunahuna sa pagpanapaw, ug wala sila makaila kang Yahweh.
“Ìṣe wọn kò gbà wọ́n láààyè láti padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wọn. Ẹ̀mí àgbèrè wà ni ọkàn wọn, wọn kò sì mọ Olúwa.
5 Ang pagkamagarbohon sa Israel ang nagpamatuod batok kaniya; busa mapandol ang Israel ug ang Efraim sa ilang kasal-anan; ug mapandol usab ang Juda uban kanila.
Ìgbéraga Israẹli ń jẹ́rìí lé wọn; àwọn ọmọ Israẹli, àti Efraimu pàápàá kọsẹ̀ nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Juda náà sì kọsẹ̀ pẹ̀lú wọn.
6 Mangadto sila uban sa panon sa ilang mga karnero ug baka aron sa pagpangita kang Yahweh, apan dili nila siya makaplagan, tungod kay gipahilayo niya ang iyang kaugalingon gikan kanila.
Nígbà tí wọ́n bá lọ pẹ̀lú agbo ẹran àti ọ̀wọ́ ẹran wọn láti wá Olúwa, wọn kò ní rí i, ó ti yọ ara rẹ̀ kúrò láàrín wọn.
7 Nagmaluibon sila kang Yahweh, tungod kay nag-anak sila ug dili ilang mga anak. Karon pagatukbon sila sa pagsaulog sa bag-ong bulan uban ang ilang mga kaumahan.
Wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Olúwa wọ́n sì bí àwọn àjèjì ọmọ. Nísinsin yìí, ọdún oṣù tuntun wọn, ni yóò pa wọn run pẹ̀lú ìpín wọn.
8 Patingoga ang budyong sa Gibea, ug ang trumpeta sa Rama. Patingoga ang singgit sa panaggubat sa Bet Aven: 'Gukdon namo kamo, Benjamin!'
“Fọn fèrè ní Gibeah, kí ẹ sì fun ìpè ní Rama. Ẹ pariwo ogun ní Beti-Afeni; máa wárìrì, ìwọ Benjamini.
9 Mahimong biniyaan ang Efraim sa adlaw sa pagsilot. Taliwala sa mga tribo sa Israel akong gipahayag ang sigurado nga mahitabo.
Efraimu yóò di ahoro ní ọjọ́ ìbáwí láàrín àwọn ẹ̀yà Israẹli, Mo sọ ohun tí ó dájú.
10 Sama niadtong nagsibog sa utlanan nga bato ang mga pangulo sa Juda. Ibubo ko kanila ang akong kapungot sama sa tubig.
Àwọn olórí Juda dàbí àwọn tí í máa yí òkúta ààlà kúrò. Èmi ó tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí bí ìkún omi.
11 Madugmok ang Efraim; madugmok siya sa paghukom, tungod kay miuyon siya sa paglakaw sunod sa mga diosdios.
A ni Efraimu lára, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ ní ìdájọ́, nítorí pé, ó pinnu láti tẹ̀lé òrìṣà.
12 Busa mahimo akong sama sa mananap ngadto sa Efraim, ug sama sa pagkadunot ngadto sa balay sa Juda.
Mo dàbí kòkòrò aṣọ sí Efraimu, Mo sì dàbí ìdin ara Juda.
13 Sa dihang nakita sa Efraim ang iyang balatian, ug nakita sa Juda ang iyang samad, unya miadto ang Efraim sa Asiria, ug nagpadala ang Juda ug mga mensahero ngadto sa bantogang hari. Apan wala siya makahimo sa pagtambal kaninyo nga katawhan o sa pag-ayo sa inyong samad.
“Nígbà ti Efraimu ri àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ojú egbò rẹ̀ ni Efraimu bá tọ ará Asiria lọ, ó sì ránṣẹ́ sí ọba ńlá náà fún ìrànlọ́wọ́. Ṣùgbọ́n kò le è wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ni kò le wo ojú egbò rẹ̀ jinná.
14 Busa mahimo akong sama sa liyon ngadto sa Efraim, ug sama sa batan-ong liyon ngadto sa balay sa Juda. Ako, bisan ako, mokuniskunis ug mobiya; pagabihagon ko sila, ug walay bisan kinsa nga makaluwas kanila.
Nítorí pé, èmi ó dàbí kìnnìún sí Efraimu, bí i kìnnìún ńlá sí ilé Juda. Èmi ó fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ èmi ó sì lọ; Èmi ó gbé wọn lọ, láìsí ẹni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀.
15 Molakaw ako ug mobalik sa akong dapit, hangtod nga ilhon nila ang ilang pagkasad-an ug mangita sa akong panagway, hangtod nga tinud-anay nila akong pangitaon sa ilang kalisdanan.”
Nígbà náà ni èmi ó padà lọ sí ààyè mi títí di ìgbà tí wọn ó fi gbà pé àwọn jẹ̀bi wọn yóò sì wá ojú mi nínú ìpọ́njú wọn, wọn ó fi ìtara wá mi.”

< Hosea 5 >