< 2 Samuel 22 >

1 Giawit ni David ngadto kang Yahweh ang mga pulong niini nga awit sa adlaw nga giluwas siya ni Yahweh gikan sa kamot sa tanan niyang mga kaaway, ug gikan sa kamot ni Saul.
Dafidi sì kọ ọ̀rọ̀ orin yìí sí Olúwa ní ọjọ́ tí Olúwa gbà á kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀, àti kúrò lọ́wọ́ Saulu.
2 Nag-ampo siya, “Si Yahweh ang akong bato, ang akong salipdanan, nga maoy nagluwas kanako.
Ó sì wí pé, “Olúwa ni àpáta mi, àti Olùgbàlà mi;
3 Ang Dios mao ang akong bato. Modangop ako kaniya. Siya ang akong taming, ang budyong sa akong kaluwasan, ang akong lig-on nga tagoanan, ug ang akong dalangpanan, siya mao ang nagluwas kanako gikan sa kaalaotan.
Ọlọ́run mi, àpáta mi, nínú ẹni tí èmi ní ààbò, àti ìwo ìgbàlà mi, ibi ìsádi gíga mi. Àti ibi ìlùmọ̀ mi, Olùgbàlà mi; ìwọ ni ó ti gbà mí kúrò lọ́wọ́ ìwà ipá.
4 Magtawag ako kang Yahweh, nga mao ang angayan nga pagadayegon, ug maluwas ako gikan sa akong mga kaaway.
“Èmi ké pe Olúwa, tí ó yẹ láti máa yìn, ó sì gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
5 Kay gipalibotan ako sa mga balod sa kamatayon, milumos kanako ang sulog nga katubigan sa kagub-anan.
Nígbà tí ìbìlù ìrora ikú yí mi káàkiri; tí àwọn ìṣàn ènìyàn búburú dẹ́rùbà mí.
6 Gigapos ako sa pisi sa Seol; nalit-ag ako sa bitik sa kamatayon. (Sheol h7585)
Ọ̀já isà òkú yí mi káàkiri; ìkẹ́kùn ikú dojúkọ mí. (Sheol h7585)
7 Sa akong kagul-anan nagtawag ako kang Yahweh; nagtawag ako sa akong Dios; gidungog niya ang akong tingog gikan sa iyang templo, ug ang akong pagpakitabang nahiabot ngadto sa iyang igdulungog.
“Nínú ìpọ́njú mi, èmi ké pé Olúwa, èmi sì gbé ohùn mi sókè sí Ọlọ́run mi. Ó sí gbóhùn mi láti tẹmpili rẹ̀ igbe mí wọ etí rẹ̀.
8 Unya ang kalibotan nauyog ug mikurog. Ang mga sukaranan sa kalangitan mikurog ug nauyog, tungod kay nasuko man ang Dios.
Ilẹ̀ sì mì, ó sì wárìrì; ìpìlẹ̀ ọ̀run wárìrì, ó sì mì, nítorí tí ó bínú.
9 Migula ang aso gikan sa iyang ilong, ug ang kusog nga kalayo migula gikan sa iyang baba. Ang baga misiga tungod niini.
Èéfín ti ihò imú rẹ̀ jáde wá, iná ajónirun ti ẹnu rẹ̀ jáde wá, ẹ̀yin iná bú jáde láti inú rẹ̀.
10 Giablihan niya ang kalangitan ug mikanaog siya, ug ang baga nga kangitngit anaa ilalom sa iyang mga tiil.
Ó tẹ orí ọ̀run ba pẹ̀lú, ó sì sọ̀kalẹ̀; òkùnkùn biribiri sì ń bẹ ní àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀.
11 Misakay siya sa usa ka kerubin ug milupad. Makita siya sa mga pako sa kahanginan.
Ó sì gun orí kérúbù, ó sì fò, a sì rí i lórí ìyẹ́ afẹ́fẹ́.
12 Gihimo niya nga tolda ang kangitngit sa iyang palibot, gipadag-om ang kapanganoran sa kawanangan.
Ó sì fi òkùnkùn ṣe ibùjókòó yí ara rẹ̀, àti àgbájọ omi, àní ìṣúdudu ìkùùkuu àwọ̀ sánmọ̀.
13 Tungod sa kilat nahulog ang nagbagang kalayo sa iyang atubangan.
Nípasẹ̀ ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ̀ ẹ̀yín iná ràn.
14 Nagpadalugdog si Yahweh gikan sa kalangitan. Misinggit ang Labing Halangdon.
Olúwa sán àrá láti ọ̀run wá, Ọ̀gá-ògo jùlọ sì fọhùn rẹ̀.
15 Gipangpana niya ug gipatibulaag ang iyang mga kaaway—sa makusog nga kilat ug gipangpukan sila.
Ó sì ta ọfà, ó sì tú wọn ká; ó kọ mànàmànà, ó sì ṣẹ́ wọn.
16 Unya mitungha ang tuboran sa katubigan; nadayag ang mga sukaranan sa kalibotan sa pagtawag ni Yahweh sa gubat, sa paggula sa gininhawa sa iyang ilong.
Ìṣàn ibú òkun sì fi ara hàn, ìpìlẹ̀ ayé fi ara hàn, nípa ìbáwí Olúwa, nípa fífún èémí ihò imú rẹ̀.
17 Mikunsad siya gikan sa hataas; gikuptan niya ako! Gibira niya ako gikan sa mibul-og nga tubig.
“Ó ránṣẹ́ láti òkè wá, ó mú mi; ó fà mí jáde láti inú omi ńlá wá.
18 Giluwas niya ako gikan sa kusgan kong mga kaaway, gikan niadtong nagdumot kanako, kay kusgan kaayo sila alang kanako.
Ó gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá mi alágbára, lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra mi, nítorí pé wọ́n lágbára jù mí lọ.
19 Miabot sila aron makigbatok kanako sa adlaw sa akong kagul-anan, apan si Yahweh ang akong magtatabang.
Wọ́n wá láti borí mi lọ́jọ́ ìpọ́njú mi, ṣùgbọ́n Olúwa ni aláfẹ̀yìntì mi.
20 Gidala usab niya ako sa halapad nga dapit. Giluwas niya ako tungod kay nahimuot man siya kanako.
Ó sì mú mi wá sí ààyè ńlá, ó gbà mi, nítorí tí inú rẹ̀ dún sí mi.
21 Gigantihan ako ni Yahweh sumala sa akong pagkamatarong; gibalik ako niya sibo sa kahinlo sa akong mga kamot.
“Olúwa sán án fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi; ó sì san án fún mi gẹ́gẹ́ bí mímọ́ ọwọ́ mi.
22 Kay gitipigan ko ang mga dalan ni Yahweh ug wala nagbuhat ug daotan pinaagi sa pagbiya sa akong Dios.
Nítorí pé èmi pa ọ̀nà Olúwa mọ́, èmi kò sì fi ìwà búburú yapa kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run mi.
23 Kay sa tanan niyang matuod nga kasugoan nga ania kanako; sama sa iyang mga balaod, wala ako mitalikod gikan niini.
Nítorí pé gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ ni ó wà níwájú mi; àti ní ti òfin rẹ̀, èmi kò sì yapa kúrò nínú wọn.
24 Wala usab akoy sala sa iyang atubangan, ug gilikay ko ang akong kaugalingon gikan sa sala.
Èmi sì wà nínú ìwà títọ́ sí í, èmi sì pa ara mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi.
25 Busa gibangon ako ni Yahweh sumala sa akong pagkamatarong, ngadto sa kalidad sa akong pagkahinlo diha sa iyang panan-aw.
Olúwa sì san fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi, gẹ́gẹ́ bí ìwà mímọ́ mi níwájú rẹ̀.
26 Alang niadtong matinumanon, gipakita mo ang imong kaugalingon nga matinumanon; ngadto sa mga walay ikasaway, gipakita mo ang imong kaugalingon nga walay ikasaway.
“Fún aláàánú ni ìwọ ó fi ara rẹ̀ hàn ni aláàánú, àti fún ẹni ìdúró ṣinṣin ní òdodo ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn ní ìdúró ṣinṣin ní òdodo.
27 Sa mga putli gipakita mo ang imong kaugalingon nga putli, apan matuison ka ngadto sa mga masinupakon.
Fún onínú funfun ni ìwọ fi ara rẹ hàn ní funfun; àti fún ẹni wíwọ́ ni ìwọ ó fi ara rẹ hàn ní wíwọ́.
28 Giluwas mo ang gisakit nga katawhan, apan ang imong mga mata batok sa mapagarbohon, ug gipaubos nimo sila.
Àwọn ènìyàn tí ó wà nínú ìyà ni ìwọ ó sì gbàlà; ṣùgbọ́n ojú rẹ wà lára àwọn agbéraga, láti rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.
29 Kay ikaw ang akong suga, Yahweh. Si Yahweh maoy nagpahayag sa akong kangitngit.
Nítorí ìwọ ni ìmọ́lẹ̀ mi, Olúwa; Olúwa yóò sì sọ òkùnkùn mi di ìmọ́lẹ̀.
30 Kay pinaagi kanimo makalukso ako sa ali; pinaagi sa akong Dios makaambak ako ibabaw sa paril.
Bẹ́ẹ̀ ni nítorí nípa rẹ̀ ni èmi ti la àárín ogun kọjá; nípa Ọlọ́run mi èmi ti fo odi kan.
31 Alang sa Dios, ang iyang dalan hingpit. Putli ang pulong ni Yahweh. Siya mao ang taming ngadto sa tanan nga modangop kaniya.
“Ọlọ́run yìí, pípé ni ọ̀nà rẹ̀; ọ̀rọ̀ Olúwa ni a ti dánwò. Òun sì ni asà fún gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e.
32 Kay kinsa ba ang Dios gawas kang Yahweh lamang, ug kinsa ba ang bato kondili ang atong Dios?
Nítorí ta ni Ọlọ́run, bí kò ṣe Olúwa? Ta ni àpáta, bí kò ṣe Ọlọ́run wa.
33 Ang Dios ang akong dalangpanan, ug gigiyahan niya ang tawong walay ikasaway diha sa iyang agianan.
Ọlọ́run alágbára ni ó fún mi ní agbára, ó sì sọ ọ̀nà mi di títọ́.
34 Gihimo niyang idlas ang akong mga tiil sama sa binaw ug gipahimutang ako sa hataas nga kabungtoran.
Ó ṣe ẹsẹ̀ mi bí ẹsẹ̀ abo àgbọ̀nrín; ó sì mú mi dúró ní ibi gíga mi.
35 Gibansay niya ang akong mga kamot sa pagpakiggubat, ug ang akong mga bukton sa pagbawog sa tumbaga nga pana.
Ó kọ́ ọwọ́ mi ní ogun jíjà; tó bẹ́ẹ̀ tí apá mi fa ọrun idẹ.
36 Gihatag mo kanako ang taming sa imong kaluwasan, ug ang imong pabor naghimo kanako nga bantogan.
Ìwọ sì ti fún mi ní asà ìgbàlà rẹ̀; ìrẹ̀lẹ̀ rẹ̀ sì ti sọ mí di ńlá.
37 Naghimo ka ug halapad nga dapit aron katumban sa akong mga tiil, aron dili madalin-as ang akong mga tiil.
Ìwọ sì sọ ìtẹ̀lẹ̀ di ńlá ní abẹ́ mi; tó bẹ́ẹ̀ tí ẹsẹ̀ mi kò fi yọ̀.
38 Gigukod ko ang akong mga kaaway ug gigun-ob sila. Wala ako miatras hangtod nga mangalaglag sila.
“Èmi ti lépa àwọn ọ̀tá mi, èmi sì ti run wọ́n, èmi kò pẹ̀yìndà títí èmi fi run wọ́n.
39 Gitukob ko ug gidugmok sila; nga dili na sila makabarog pa. Nangapukan sila sa akong tiilan.
Èmi ti pa wọ́n run, èmi sì ti fọ́ wọn, wọn kò sì le dìde mọ́, wọ́n ṣubú lábẹ́ mi.
40 Gilig-on mo ako sama sa bakos sa pagpakiggubat; gibutang mo ubos sa akong pagmando kadtong mibatok kanako.
Ìwọ sì ti fi agbára dì mí ní àmùrè fún ìjà; àwọn tí ó ti dìde sí mi ni ìwọ sì ti tẹ̀ lórí ba fún mi.
41 Gihatag mo kanako ang tangkugo sa akong mga kaaway; gipukan ko kadtong nagdumot kanako.
Ìwọ sì mú àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà fún mi, èmi ó sì pa àwọn tí ó kórìíra mi run.
42 Nanaghilak sila aron tabangan, apan walay bisan usa nga miluwas kanila; nagtuaw sila ngadto kang Yahweh, apan wala niya sila tubaga.
Wọ́n wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan láti gbà wọ́n; wọ́n wo Olúwa, ṣùgbọ́n kò dá àwọn lóhùn.
43 Gidugmok ko sila sa pino sama sa abog sa yuta, gipino ko sila sama sa yuta sa kadalanan.
Nígbà náà ni èmi sì gún wọn wẹ́wẹ́ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, èmi sì tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ bí ẹrẹ̀ ìta, èmi sì tẹ́ wọn gbọrọ.
44 Giluwas usab nimo ako gikan sa panag-away sa kaugalingon kong katawhan. Nagpabilin ako ingon nga pangulo sa mga nasod. Ang katawhan nga wala ko mailhi nag-alagad kanako.
“Ìwọ sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ ìjà àwọn ènìyàn mi, ìwọ pa mi mọ́ ki èmi lè ṣe olórí àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè. Àwọn ènìyàn tí èmi kò tí mọ̀ yóò máa sìn mí.
45 Napugos ang mga langyaw sa pagyukbo nganhi kanako. Sa dihang madungog nila ako, motuman sila kanako.
Àwọn àjèjì wá láti tẹríba fún mi; bí wọ́n bá ti gbúròó mi, wọ́n á sì gbọ́ tèmi.
46 Ang mga langyaw miabot nga nagapangurog gikan sa ilang lig-on nga mga salipdanan.
Àyà yóò pá àwọn àlejò, wọ́n ó sì fi ìbẹ̀rù sá kúrò níbi kọ́lọ́fín wọn.
47 Mabuhi si Yahweh! Hinaot nga pagadayegon ang bato. Mapasidunggan unta ang Dios, ang bato sa akong kaluwasan.
“Olúwa ń bẹ́; olùbùkún sì ni àpáta mi! Gbígbéga sì ni Ọlọ́run àpáta ìgbàlà mi.
48 Mao kini ang Dios nga mobalos ug silot alang kanako, ang Dios nga maoy maghatod sa katawhan ubos sa akong pagmando.
Ọlọ́run ni ẹni tí ń gbẹ̀san mi, àti ẹni tí ń rẹ àwọn ènìyàn sílẹ̀ lábẹ́ mi.
49 Gipalingkawas niya ako gikan sa akong mga kaaway. Tinuod gayod, gituboy mo ako sa kahitas-an niadtong nakigbatok kanako. Giluwas mo ako gikan sa mga tawong daotan.
Àti ẹni tí ó gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi. Ìwọ sì gbé mi sókè ju àwọn tí ó kórìíra mi lọ; ìwọ sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọkùnrin oníwà ipá.
50 Busa maghatag ako ug pagpasalamat nganha kanimo, Yahweh, taliwala sa mga nasod; mag-awit ako ug mga pagdayeg nganha sa imong ngalan.
Nítorí náà èmi ó fi ọpẹ́ fún ọ, Olúwa, láàrín àwọn àjèjì orílẹ̀-èdè, èmi ó sì kọrin sí orúkọ rẹ.
51 Mohatag ang Dios ug dakong kadaogan ngadto sa hari, ug gipakita niya ang iyang matinud-anong kasabotan ngadto sa tawo nga iyang dinihogan, ngadto kang David ug ngadto sa iyang mga kaliwat hangtod sa kahangtoran.”
“Òun ni ilé ìṣọ́ ìgbàlà fún ọba rẹ̀; ó sì fi àánú hàn fún ẹni àmì òróró rẹ̀, fún Dafidi, àti fún irú-ọmọ rẹ̀ títí láéláé.”

< 2 Samuel 22 >