< Псалми 51 >

1 За първия певец, псалом на Давида, когато пророк Натан дойде при него, след като беше влязъл той при Вистсавия. Смили се за мене, Боже, според милосърдието Си; според множеството на благите Си милости и изличи беззаконията ми.
Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nígbà ti wòlíì Natani tọ wá, lẹ́yìn tí Dafidi dá ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè rẹ̀ pẹ̀lú Batṣeba. Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ àánú rẹ̀ kí o sì pa gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.
2 Измий ме съвършено от беззаконието ми, И очисти ме от греха ми.
Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi nù kúrò kí o sì wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi!
3 Защото престъплението си аз признавам, И грехът ми е винаги пред мене.
Nítorí mo mọ̀ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi, nígbà gbogbo ni ẹ̀ṣẹ̀ mi wà níwájú mi.
4 На Тебе, само на Тебе, съгреших, И пред тебе сторих това зло; Признавам това, за да бъдеш оправдан когато говориш, когато говориш, И излезеш непорочен, когато съдиш.
Sí ọ, ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀ sí ni mo sì ṣe búburú níwájú rẹ̀, kí a lè dá ọ láre nígbà tí ìwọ bá ń sọ̀rọ̀, kí o sì le wà láìlẹ́bi, nígbà tí ìwọ bá ń ṣe ìdájọ́.
5 Ето родих се в нечестие, И в грях ме зачна майка ми.
Nítòótọ́, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni a ti bí mi, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni ìyá mí sì lóyún mi.
6 Ето, понеже желаеш искреност вътре в човека, Научи ме мъдрост в скришното на сърцето ми.
Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ ní inú; ìwọ kọ́ mi ní ọgbọ́n ní ìhà ìkọ̀kọ̀.
7 Поръси ме с исоп, и ще бъда чист; Измий ме, и ще стана по-бял от сняг.
Wẹ̀ mí pẹ̀lú ewé hísópù, èmi yóò sì mọ́; fọ̀ mí, èmi yóò sì funfun ju yìnyín lọ.
8 Дай ми да чуя радост и веселие, За да се зарадват костите, които си строшил.
Jẹ́ kí n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn; jẹ́ kí gbogbo egungun tí ìwọ ti run kí ó máa yọ̀.
9 Отвърни лицето Си от греховете ми. И всичките ми беззакония изличи.
Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi kí o sì pa gbogbo àwọn àìṣedéédéé mi rẹ́.
10 Сърце чисто сътвори в мене, Боже. И дух постоянен обновявай вътре в мене,
Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọ́run, kí o sì tún ẹ̀mí dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.
11 Да не ме отхвърлиш от присъствието Си, Нито да отнемеш от мене Светия Си Дух.
Má ṣe jù mi nù kúrò níwájú rẹ, kí o má ṣe gba Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ lọ́wọ́ mi.
12 Повърни ми радостта на спасението Си: И освобождаващият Дух нека ме подкрепи.
Mú ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ mí wá, kí o sì fún mi ní ẹ̀mí ìfẹ́, tí yóò mú mi dúró.
13 Тогава ще науча престъпниците на Твоите пътища, И грешниците ще се обърнат към Тебе.
Nígbà náà ni èmi yóò máa kọ́ àwọn olùrékọjá ní ọ̀nà rẹ, àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò sì yí padà sí ọ.
14 Избави ме от виновността за кръвта, Боже, Боже на спасението ми; И езикът ми ще пее високо за Твоята правда.
Gbà mí kúrò lọ́wọ́ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ Ọlọ́run ìgbàlà mi, ahọ́n mi yóò sì máa kọrin òdodo rẹ kíkan.
15 Господи, отвори устните ми; И устата ми ще разгласят Твоята хвала.
Olúwa, ṣí mi ní ètè mi gbogbo, àti ẹnu mi yóò sì máa kéde ìyìn rẹ.
16 Защото не щеш да Ти принеса жертва; Всеизгаряния не Ти са угодни.
Nítorí ìwọ kò ní inú dídùn sí ẹbọ, tí èmi kò bá mú wá; Ìwọ kò ní inú dídùn sí ọrẹ ẹbọ sísun.
17 Жертви на Бога са дух съкрушен; Сърце съкрушено и разкаяно, Боже, Ти няма да презреш.
Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.
18 Стори добро на Сион според благоволението Си; Съгради стените на Ерусалим.
Ṣe rere ní dídùn inú rẹ sí Sioni, ṣe rere; tún odi Jerusalẹmu mọ.
19 Тогава благоволението Ти ще бъде в жертви на правда, В приноси и всеизгаряния; Тогава ще принасят юници на олтара Ти.
Nígbà náà ni inú rẹ yóò dùn sí ẹbọ òdodo, pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun àti ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ọrẹ ẹbọ sísun, nígbà náà ni wọn yóò fi akọ màlúù rú ẹbọ lórí pẹpẹ rẹ.

< Псалми 51 >