< Philippians 1 >
1 Bulu mba Timoti igran Yesu, hi bi wa ba ziba ni mi Yesu wa ba he ni Filibi ni biwa ba nji coci ni dikinoni.
Paulu àti Timotiu, àwọn ìránṣẹ́ Jesu Kristi, Sí gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ nínú Kristi Jesu tí ó wà ní Filipi, pẹ̀lú àwọn alábojútó àti àwọn díákónì:
2 Ndu zizi he ni yi ni' si Irji tiembu nda tie Bacimbu Yesu Kristi
Oore-ọ̀fẹ́ sí yín, àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Olúwa wa Jesu Kristi.
3 Mi ngri ni Rji ni nton wa' mi tamre mbia.
Mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi ní gbogbo ìgbà tí mo bá rántí yín.
4 Ko ni tanyi wami tie bre Irji ni yiwu, mi tie bre ni ngryi.
Nínú gbogbo àdúrà mi fún un yín, èmi ń fi ayọ̀ gbàdúrà,
5 Mi ngryi yi wu wa bi wu ta ni to du Rji ni fin umumum'e har ye zizan.
nítorí ìdàpọ̀ yín nínú ìyìnrere láti ọjọ́ kìn-ín-ní wá títí di ìsinsin yìí.
6 Mi kpa nyme ni kpi biyi wawu, wawu wa ati tun ndinti ni mi bi arji kle du nra bi ni ye ivri Rji.
Ohun kan yìí sá à dá mi lójú pé, ẹni tí ó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere nínú yín, yóò ṣe àṣepé rẹ̀ títí di ọjọ́ náà tí Jesu Kristi yóò dé.
7 Abi na kyi wa mi wo itre ndindi ni tun bi bi he ni sroun mu. Bi yi wawu bi gpo gba mu ni mi dun Rji ni tre ma.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mi láti ro èyí nípa gbogbo yín, nítorí tí mo fi yín sọ́kàn, bí mo tilẹ̀ wà nínú ìdè tàbí ìdáhùn ẹjọ́, àti ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ìyìnrere, gbogbo yín jẹ́ alábápín oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run pẹ̀lú mi.
8 Rji ton sroun mu wa mi hewu niyi ni son wu Kristi ye ni yi
Nítorí Ọlọ́run ni ẹlẹ́rìí mi, bí mo ti ń ṣàfẹ́rí yín gidigidi nínú ìfẹ́ Jesu Kristi.
9 Mi bra ni yi wu dei son bi ndi kwuci ni tre Rji.
Èyí sì ni àdúrà mi: pé kí ìfẹ́ yín lè máa pọ̀ síwájú àti síwájú sí i nínú ìfẹ́ àti ìmọ̀ ìjìnlẹ̀,
10 In bremu niyiwu dei tsre ndidi ni kon wa abi. Mi bre niyiwu ndi yi tsre gye gyer meni kon Rji.
kí ẹ̀yin kí ó lè ní òye ohun tí ó dára jùlọ; kí ó sì jásí òdodo àti aláìjẹ́ ohun ìkọ̀sẹ̀ títí di ọjọ́ dídé Jesu Kristi,
11 Wayi akiyi di Rji ni srendinbi wa Yesu ni nun wa inde Rji ni bi.
lẹ́yìn ìgbà ti ẹ ti kún fún àwọn ìwà òdodo láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, fún ògo àti ìyìn Ọlọ́run.
12 I mri vayi mi son duyi ton ikpi mba sisre dun ha'ni tre Rji.
Ǹjẹ́ èmi fẹ́ kí ẹ̀yin kí ó mọ̀, ará, pé ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí mi jásí àtẹ̀gùn sí ìlọsíwájú ìyìnrere.
13 Don tre Rji iya si kpa biwa mba sre ni kon Yesu.
Nítorí ìdí èyí, ó ti hàn gbangba sí gbogbo àwọn ẹ̀ṣọ́ ààfin àti sí àwọn ẹlòmíràn wí pé mo wà nínú ìdè fún Kristi.
14 Imri vayi gbugbu mba kri gbangban wa mba to me nimi sara, nda kri gban gban ni zan mba handa tre tre Rji
Nítorí ìdè mi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ará nínú Olúwa ni a ti mú lọ́kàn le láti sọ̀rọ̀ Ọlọ́run sí i pẹ̀lú ìgboyà àti láìbẹ̀rù.
15 Mba ri mba tre tre Rji ni mi fu ni son sroun, mbari ni sroun ndiki.
Òtítọ́ ni pé àwọn ẹlòmíràn tilẹ̀ ń fi ìjà àti ìlara wàásù Kristi, ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn sì ń fi inú rere ṣe é.
16 Bi tre tre Rji ni sroun ndindi mbato mba zi me nde me kle du tre Rji.
Àwọn kan ń fi ìjà wàásù Kristi, kì í ṣe pẹ̀lú òtítọ́ inú, wọ́n ń gbèrò láti fi ìpọ́njú kún ìdè mi.
17 Mbari mba tre tre Rji dun son tun, ni sroun meme, ni impre mba ndi mba zitrenya ni mi yan.
Àwọn kan ẹ̀wẹ̀ si ń fi ìfẹ́ ṣe é, nítorí tí wọ́n mọ̀ pé a gbé mi dìde láti dá ààbò bo iṣẹ́ ìyìnrere.
18 Ni kon meme, kon ni meme bi tre tre Yesu, me gri, ra zizan me ngryi.
Kí ló tún kù? Kìkì í pé níbi gbogbo, ìbá à ní ìfẹ̀tànṣe tàbí ni ti òtítọ́ a sá à n wàásù Kristi, èmi sì ń yọ̀ nítorí èyí. Nítòótọ́, èmi ó sì máa yọ̀,
19 Ni kon yi mi gbukbun ni sara. wa ni he wa bi bra nimu, ni zo Ruhu Yesu Kristi.
nítorí tí mo mọ̀ pé èyí ni yóò yọrí sí ìgbàlà fún mi láti inú àdúrà yín wá, àti ìfikún ẹ̀mí Jesu Kristi.
20 A bra mu ni son mu, mi na sha sha nan ni sroun mu wawu, Yesu son ni sroun mu kon mi ni ri kon kwu.
Gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn àti ìrètí mi pé kí ojú kí ó má ṣe ti mi ní ohunkóhun, ṣùgbọ́n kí èmi kí ó le máa ni ìgboyà ní ìgbà gbogbo àti nísinsin yìí, kí a lè ti ipasẹ̀ mi gbé Kristi ga lára mi, ìbá à ṣe pé mo wà láààyè, tàbí mo kú.
21 Ndi me he ni re a Kristi, ndi mi kwu a kwuci.
Nítorí, ní ti èmi, láti wa láààyè jẹ́ Kristi, láti kú pẹ̀lú sì jẹ́ èrè fún mi.
22 Wa mi tsre ni kpa wa zo me wu tre Rji me ma to wa me huna.
Ṣùgbọ́n bí èmi bá le è ṣe iṣẹ́ ti ó ni àpẹẹrẹ nípa wíwà láààyè nínú ara, ṣùgbọ́n ohun ti èmi ó yàn, èmi kò mọ̀.
23 Ha ri mba ba mba mre mu Mremu ndi bri wirji yi ndi he ni Almasihu wa yi ni fin.
Ṣùgbọ́n èmi n ṣiyèméjì, nítorí ti èmi fẹ́ láti lọ kúrò nínú ayé yìí, láti wà lọ́dọ̀ Kristi; nítorí ó dára púpọ̀ jù:
24 Tsre mu ni kpa alele ni yiwu.
síbẹ̀ láti wà láààyè jẹ́ àǹfààní nítorí tiyín.
25 Mi to wa yi alele ani ha na kiyi, wa mi he niyi, ni tse sroun bi, ni mi sroun bi.
Bí èyí sì ti dá mi lójú, mo mọ̀ pé èmi ó dúró, èmi ó sì máa wà pẹ̀lú yín fún ìtẹ̀síwájú àti ayọ̀ yín nínú ìgbàgbọ́,
26 Yagan bi ni mi Almasihu Kristi a ni gji kwui do kba ye ni yi.
kí ìṣògo yín kí ó lè di púpọ̀ gidigidi nínú Jesu Kristi, àti nínú mi nípa ìpadà wá mi sọ́dọ̀ yín.
27 Tsre gyegyer ni kon Rji, ko mi ye komina ye na mi ku wo bi kyi gbegba ni mi enbru ndidi. me gri ndu mi wo ndi bisi tsre gyegyer ni kon Rji.
Ohun yówù kó ṣẹlẹ̀, ẹ jẹ́ kí ìgbé ayé yín ri gẹ́gẹ́ bí ìyìnrere Kristi: pé yálà bi mo tilẹ̀ wá wò yín, tàbí bí èmi kò wá, kí èmi kí ó lè máa gbúròó bí ẹ ti ń ṣe, pé ẹ̀yin dúró ṣinṣin nínú Ẹ̀mí kan, ẹ̀yin jùmọ̀ jìjàkadì nítorí ìgbàgbọ́ ìyìnrere, pẹ̀lú ọkàn kan.
28 Na klu sistri biwa mbana son yina. ni mba wu a kwu ni tawu a kon ndurh ma wayi rji ni Rji.
Kí ẹ má sì jẹ́ ki àwọn ọ̀tá dẹ́rùbà yin ni ohunkóhun: èyí tí í ṣe àmì tí ó dájú pé a ó pa wọ́n run, ṣùgbọ́n Ọlọ́run tìkára rẹ̀ ni yóò gbà yin là.
29 Mba te didi niwu dun Almasihu ana kpa Almasihu megen na, bi sha ya men.
Nítorí tí a ti fún yin ni àǹfààní, kì í ṣe láti gba Kristi gbọ́ nìkan, ṣùgbọ́n láti jìyà nítorí rẹ̀ pẹ̀lú.
30 Bizi shaya iri mu wa bi zi to, wa bi zi wo sha yan.
Ẹ sì máa ja ìjà kan náà, èyí ti ẹ̀yin ti ri, ti ẹ sì ti gbọ́ pé èmi n jà pẹ̀lú.