< Sefanaia 2 >

1 Dilia da hame gogosiasu fi! Dilia asigi dawa: su moloma!
Ẹ kó ara yín jọ pọ̀, àní ẹ kó ra yín jọ pọ̀ orílẹ̀-èdè tí kò ní ìtìjú,
2 Dilia da gisi a: le fasi defele amo biosa: besa: le, amola Hina Gode Ea gia: i bagade ougi hou dilima doaga: sa: besa: le, dilia asigi dawa: su moloma!
kí a tó pa àṣẹ náà, kí ọjọ́ náà tó kọjá bí ìyàngbò ọkà, kí gbígbóná ìbínú Olúwa tó dé bá a yín, kí ọjọ́ ìbínú Olúwa kí ó tó dé bá a yín.
3 Hina Godema sinidigima! Soge ganodini asaboi dunu amo da Gode Ea hamoma: ne sia: i nabawane hamosa, dilia Hina Godema sinidigima! Moloidafa hamoma amola Hina Gode ba: ma: ne, dilia hou fofonoboma! Amabela? Dilia da amo esoga, Hina Gode da Ea ougi hou ba: ma: ne olelesea, se nabasu hame ba: mu.
Ẹ wá Olúwa, gbogbo ẹ̀yin onírẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ náà, ẹ̀yin tí ń ṣe ohun tí ó bá pàṣẹ. Ẹ wá òdodo, ẹ wá ìrẹ̀lẹ̀ pẹ̀lú, bóyá á ó pa yín mọ́ ní ọjọ́ ìbínú Olúwa.
4 Ga: isa amola A: segelone moilai bai bagade ela ganodini dunu afae esalebe hame ba: mu. Asedode moilai bai bagade dunu da eso afaega esomogoa gadili sefasi dagoi ba: mu. Egelone moilai bai bagade dunu fi da gadili sefasi dagoi ba: mu.
Nítorí pé, a ó kọ Gasa sílẹ̀, Aṣkeloni yóò sì dahoro. Ní ọ̀sán gangan ni a ó lé Aṣdodu jáde, a ó sì fa Ekroni tu kúrò.
5 Dilia Filisidini dunu amo da hano wayabo bagade bega: esala! Dilia amola da wadela: lesi dagoi ba: mu. Hina Gode da dilima se nabasu imunusa: ilegei dagoi. E da dili huluane wadela: lesili, dilia dunu afae esalebe hame ba: mu.
Ègbé ni fún ẹ̀yin tí ń gbé etí Òkun, ẹ̀yin ènìyàn ara Kereti; ọ̀rọ̀ Olúwa dojúkọ ọ́, ìwọ Kenaani, ilẹ̀ àwọn ara Filistini. “Èmi yóò pa yín run, ẹnìkan kò sì ní ṣẹ́kù nínú yín.”
6 Dilia soge huluane hano wayabo gadenene da dunu hame esalebe, moifufu sogebi fawane ba: mu. Amogawi sibi ouligisu dunu ilia diasu amola sibi gagoi amo fawane dialebe ba: mu.
Ilẹ̀ náà ní etí Òkun, ni ibùgbé àwọn ará Kereti, ni yóò jẹ́ ibùjókòó fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn àti agbo àgùntàn.
7 Amola Yuda fi hame bogoi esalebe dunu da misini, dilia soge lale fimu. Ilia sibi amola bulamagau wa: i da amogawi afugisimu. Amola dunu da A: segelone moilai bai bagade diasu ili ganodini golamu. Amola ilia Hina Gode da ili ouligimu, amola ilia da bu hahawane bagade gaguiwane fifi lalumu.
Agbègbè náà yóò sì jẹ́ ti ìyókù àwọn ilé Juda, níbẹ̀ ni wọn yóò sì ti rí koríko fún ẹran. Ní ilé Aṣkeloni ni wọn yóò dùbúlẹ̀ ni àṣálẹ́. Olúwa Ọlọ́run wọn yóò bẹ̀ wọn wò, yóò sì yí ìgbèkùn wọn padà.
8 Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Moua: be amola A: mone fi dunu da Na fi dunu ilima gadele sia: su, amola ilima dafama: ne sia: su amola ilia soge lama: ne hidale nodone sia: su, Na da nabi dagoi.
“Èmi ti gbọ́ ẹ̀gàn Moabu, àti ẹlẹ́yà àwọn Ammoni, àwọn tó kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi, tí wọ́n sì ti gbé ara wọn ga sí agbègbè wọn.
9 Na da Isala: ili fi ilia Fifi Ahoanusu Godedafa! Amola Na da dafawanedafa amane ilegele sia: sa. Na da Sodame amola Goumola moilai bai bagade wadela: lesi, amo defele Na da Moua: be amola A: mone wadela: lesimu. Ilia sogega da sali dogosu gelabo bagohame ba: mu amola wadela: lesi dagoiba: le bu hahamomu da hamedei ba: mu. Wadela: i gisi da amo soge dedebomu. Na fi dunu (Isala: ili fi) amo da hame bogoi esalebe, da Moua: be amola A: mone ilia liligi amola ilia soge gegene lamu.”
Nítorí náà, bí Èmi tí wà,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn Israẹli wí, “nítòótọ́ Moabu yóò dàbí Sodomu, àti Ammoni yóò sì dàbí Gomorra, ibi tí ó kún fún yèrèpè, àti ìhó iyọ̀ àti ìdahoro títí láéláé. Ìyókù àwọn ènìyàn mi yóò kó wọn; àwọn tí ó sì yọ nínú ewu ní orílẹ̀-èdè mi ni yóò jogún ilẹ̀ wọn.”
10 Moua: be amola A: mone fi dunu da gasa fili, Hina Gode Bagadedafa amo Ea fi dunu ilima gadele bagade sia: i. Amaiba: le, ilia da se iasu bagade ba: mu.
Èyí ni ohun tí wọn yóò gbà padà nítorí ìgbéraga wọn, nítorí wọ́n kẹ́gàn, wọn sì ti fi àwọn ènìyàn Olúwa àwọn ọmọ-ogun ṣe ẹlẹ́yà.
11 Hina Gode da ili bagade beda: ma: ne hamomu. E da osobo bagade ogogosu ‘gode’ liligi huluane dafawane wadela: lesimu. Amasea, fifi asi gala dunu huluanedafa da ilia soge afae afae ganodini, Ema nodone sia: ne gadomu.
Olúwa yóò jẹ́ ìbẹ̀rù fún wọn; nígbà tí Òun bá pa gbogbo òrìṣà ilẹ̀ náà run. Orílẹ̀-èdè láti etí odò yóò máa sìn, olúkúlùkù láti ilẹ̀ rẹ̀ wá.
12 Amola Hina Gode da Idioubia fi dunu medole legemu.
“Ẹ̀yin Etiopia pẹ̀lú, a ó fi idà mi pa yín.”
13 Hina Gode da Ea gasaga, amo Asilia soge wadela: lesimu. E da Ninefe moilai bai bagade wadela: lesimu. Amo da dunu hame esalebe, mugului dagoi, hano hamedene hafoga: i soge agoane ba: mu.
Òun yóò sì na ọwọ́ rẹ̀ sí apá àríwá, yóò sì pa Asiria run, yóò sì sọ Ninefe di ahoro, àti di gbígbẹ bí aginjù.
14 Amasea, amoga da bulamagau, sibi wa: i amola ohe fi hisu hisu ilia fawane esalebe ba: mu. Ea mugulubi amo ganodini da baou esalumu. Ilia da diasu logo holei gelabodili gugumuni imunu. Ninefe moilai bai bagade dobea fei dolo ifa da hiougili fasi dagoi ba: mu.
Agbo ẹran yóò sì dùbúlẹ̀ ni àárín rẹ̀, àti gbogbo ẹranko àwọn orílẹ̀-èdè. Òwìwí aginjù àti ti n kígbe ẹyẹ òwìwí yóò wọ bí ẹyẹ ni ọwọ̀n rẹ̀. Ohùn wọn yóò kọrin ni ojú fèrèsé, ìdahoro yóò wà nínú ìloro ẹnu-ọ̀nà, òun yóò sì ṣẹ́ ọ̀pá kedari sílẹ̀.
15 Ninefe fi dunu ilisu da gasa bagade amola hahawane gaga: i dagoi ilisu dawa: sa. Ilia moilai bai bagade da osobo bagade moilai bai bagade huluane baligi dagoi ilisu dawa: sa. Be ilia moilai bai bagade da wadela: lesi dagoi ba: mu. Ea sogebi da dunu hame esalebe hamedei soge agoane ba: mu, amola amo ganodini sigua ohe fi fawane esalebe ba: mu. Dunu huluane da amo sogebi bobaligisia, fofogadigili hagamu.
Èyí ni ìlú aláyọ̀ tí ó ń gbé láìléwu. Ó sì sọ fun ara rẹ̀ pé, “Èmi ni, kò sì sí ẹnìkan tí ó ń bẹ lẹ́yìn mi.” Irú ahoro wo ni òun ha ti jẹ́, ibùgbé fún àwọn ẹranko igbó! Gbogbo ẹni tí ó bá kọjá ọ̀dọ̀ rẹ̀ yóò fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà, wọ́n yóò sì gbọn ẹsẹ̀ wọn.

< Sefanaia 2 >