< Sefanaia 1 >

1 Eso amoga hina bagade Yousaia (A: mone ea mano) da Yuda soge ouligisu, amo esoha Hina Gode da Sefanaiama sia: ne i. (Sefanaia da Giusai amalu Gedalaia amalu A: malaia amalu hina bagade Hesigaia amo ilia egaga fi dunu esalu.)
Sí olórí akọrin lórí ohun èlò orin olókùn mi. Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Sefaniah ọmọ Kuṣi, ọmọ Gedaliah, ọmọ Amariah, ọmọ Hesekiah, ní ìgbà Josiah ọmọ Amoni ọba Juda.
2 Hina Gode da amane sia: i, “Na da osobo bagadega esalebe liligi huluane gugunufinisisimu.
“Èmi yóò mú gbogbo nǹkan kúrò lórí ilẹ̀ náà pátápátá,” ni Olúwa wí.
3 Na da dunu fi huluane, ohe fi, sio amola menabo huluane wadela: lesimu. Wadela: i hamosu dunu huluane dafama: ne, Na da wadela: lesimu. Na da dunu fi huluane wadela: lesisia, dunu afae esalebe da hame ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
“Èmi yóò mú ènìyàn àti ẹranko kúrò; èmi yóò mú àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run kúrò, àti ẹja inú Òkun, àti ohun ìdìgbòlù pẹ̀lú àwọn ènìyàn búburú; èmi yóò ké ènìyàn kúrò lórí ilẹ̀ ayé,” ni Olúwa wí.
4 Na da Yelusaleme moilai bai bagade fi amola Yuda soge fi huluane ilima se bagade imunu. Na da ilia Ba: ilema nodone sia: ne gadosu hou huluane gugunufinisimudafa. Amasea, dunu huluane da Na hou hame lalegagui gobele salasu dunu (amo da Ba: ilema hawa: hamosa) amo gogolele, bu hamedafa dawa: mu.
“Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Juda àti sórí gbogbo àwọn ènìyàn tí ń gbé ní Jerusalẹmu. Èmi yóò sì ké kúrò níhìn-ín yìí ìyókù àwọn Baali, àti orúkọ àwọn abọ̀rìṣà pẹ̀lú àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà,
5 Na da nowa dunu da diasu da: iya gado heda: le, eso amola gasumuni amola oubi amoma nodone sia: ne gadosa, amo fi huluane wadela: lesimu. Amola nowa da Nama nodone sia: ne gadosa, amola ilia lafidili Nama molole fa: no bobogemu sia: sa, be gilisili ogogosu ‘gode’ Moulege ea dioba: le sia: sa, amo amola Na da wadela: lesimu.
àti àwọn tí ń foríbalẹ̀ lórí òrùlé, àwọn tí ń sin ogun ọ̀run, àwọn tó ń foríbalẹ̀, tí wọ́n sì ń fi Olúwa búra, tí wọ́n sì ń fi Moleki búra.
6 Amola nowa dunu da Nama fa: no bobogelalu bu wadela: i hou amoma sinidigili, amola Nama Na ouligisu amola hou olelesu hame adole ba: sa, amo amola Na da wadela: lesimu,” Hina Gode da amane sia: i.
Àwọn tí ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa; àti àwọn tí kò tí wá Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì béèrè rẹ̀.”
7 Hina Gode Ea Fofada: su Eso amoga E da osobo bagade fi wadela: lesimu amo da gadenesa. Amaiba: le, dilia huluane Ea midadi ouiya: le esaloma. Hina Gode da Ea fi dunu gobele salasu hou defele, medole legemu. E da ha lai dunu amo Yuda soge liligi huluane gegenana lama: ne hiougi dagoi.
Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú Olúwa Olódùmarè, nítorí tí ọjọ́ Olúwa kù sí dẹ̀dẹ̀. Olúwa ti pèsè ẹbọ kan sílẹ̀, ó sì ti ya àwọn alápèjẹ rẹ̀ sí mímọ́.
8 Hina Gode da amane sia: sa, “Amo medole legesu esoga, Na da eagene hawa: hamosu dunu, amola hina bagade ea mano, amola nowa da ga fi ilia sia: ne gadosu hou hamonana, amo huluane ilima se imunu.
“Ní ọjọ́ ẹbọ Olúwa, Èmi yóò bẹ àwọn olórí wò, àti àwọn ọmọ ọba ọkùnrin, pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó wọ àjèjì aṣọ.
9 Na da nowa dunu da hame lalegagui agoane nodone sia: ne gadosa, amola ilia ouligisu dunu ea diasu wamolai liligi amoga nabama: ne wamolasa amola medole legesa, amo dunu huluane ilima Na da se bagade imunu.
Ní ọjọ́ náà, èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí ó yẹra láti rìn lórí ìloro ẹnu-ọ̀nà, tí wọ́n sì kún tẹmpili àwọn ọlọ́run wọn pẹ̀lú ìwà ipá àti ẹ̀tàn.
10 Hina Gode da amane sia: sa, “Amo esoga dilia da Yelusaleme moilai bai bagade Menabo Logo Ga: su amoga dibi sia: bagade nabimu. Yelusaleme moilai bai bagade gaheabolo la: idiga, dilia da didigia: su nabimu. Amola agolo damana agolo agebe ea ga: defele nabimu.
“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí, “Ohùn ẹkún yóò wà láti ìhà ibodè ẹja, híhu láti ìhà kejì wá àti ariwo ńlá láti òkè kékeré wá.
11 Amo nabasea, dilia moilai bai bagade hagudu la: idi esalebe dunu, didiga: ma amola dima! Bai dilia bidi lasu dunu huluane da bogogia: i dagoi.
Ẹ hu, ẹ̀yin tí ń gbé ní agbègbè ọjà, gbogbo àwọn oníṣòwò rẹ̀ ni a ó mú kúrò, gbogbo àwọn ẹni tí ó ń ra fàdákà ni a ó sì parun.
12 Amasea, amo esoga, Na da gamali lale, Yelusaleme ganodini hogomu. Nowa dunu da hahawane hi hou da defele dawa: lebe, amola ilisu da, ‘Hina Gode da hamedei. E da hawa: hamomu hame dawa: ,’ amane sia: sa, amo huluanema Na da se imunu.
Ní àkókò wọ̀n-ọn-nì, èmi yóò wá Jerusalẹmu kiri pẹ̀lú fìtílà, èmi ó sì fi ìyà jẹ àwọn tí kò ní ìtẹ́lọ́rùn, tí wọn sì dàbí àwọn ènìyàn tí ó sinmi sínú gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ wọn, àwọn tí wọn sì ń wí ní ọkàn wọn pé, ‘Olúwa kì yóò ṣe nǹkan kan tí ó jẹ́ rere tàbí tí ó jẹ́ búburú.’
13 Ilia gagui liligi wamolai dagoi ba: mu, amola ilia diasu wadela: lesi dagoi ba: mu. Ilia da diasu ili gagubi amoga hamedafa fifi ahoanumu, amola ilia waini efe sagabe amo ea waini hano hamedafa nanamu.”
Nítorí náà, ọrọ̀ wọn yóò di ìkógun, àti ilé wọn yóò sì run. Àwọn yóò sì kọ́ ilé pẹ̀lú, ṣùgbọ́n wọn kì yóò gbé nínú ilé náà, wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, ṣùgbọ́n wọn kì yóò mu ọtí wáìnì láti inú rẹ̀.”
14 Hina Gode Ea eso bagade da doaga: mu gadenesa. Amola gadeneidafa amola hedolowane doaga: mu. Amo eso da se nabasu bagadedafa ba: mu. Amola nimi bagade dadi gagui dunu da lobo healeiba: le, didigia: mu.
“Ọjọ́ ńlá Olúwa kù sí dẹ̀dẹ̀, ó kù sí dẹ̀dẹ̀ ó sì ń yára bọ̀ kánkán. Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, ohùn ẹkún àwọn alágbára; ní ọjọ́ Olúwa yóò korò púpọ̀,
15 Amo eso da ougi ha lasu eso, se nabasu amola bidi hamosu eso, wadela: lesisu amola mugulusu eso, amoga da gasi bagade amola alaloyo amola hadigi da bunumai mumobiga dedebomu.
ọjọ́ náà yóò jẹ́ ọjọ́ ìbínú, ọjọ́ ìrora àti ìpọ́njú, ọjọ́ òfò àti idà ọjọ́ ìdahoro ọjọ́ òkùnkùn àti ìtẹ̀ba, ọjọ́ kurukuru àti òkùnkùn biribiri,
16 Amo esoha gegesu ‘dalabede’ wesu bagade nabimu, amola gegesu dunu ilia halasu fawane nabimu. Ilia da moilai bai bagade gagili sali amola diasu sedade gado gagagula heda: i amoma doagala: beba: le, halasu bagade nabimu.
ọjọ́ ìpè àti ìpè ogun sí àwọn ìlú olódi àti sí àwọn ilé ìṣọ́ gíga.
17 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da se nabasu bagadedafa dunu fifi asi gala huluane ilima imunu. Amaiba: le, ilia da si dofoi dunu agoane ahoanumu. Ilia da Nama wadela: le hamoiba: le, ilia maga: me da hano agoane sogadigimu, amola ilia bogogia: le, ilia da: i hodo da udigili osoboga dasagia: ma: ne dialumu.”
“Èmi yóò sì mú ìpọ́njú wá sórí ènìyàn, wọn yóò sì máa rìn gẹ́gẹ́ bí afọ́jú, nítorí àwọn ti dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa. Ẹ̀jẹ̀ wọn ni a ó sì tú jáde bí eruku àti ẹran-ara wọn bí ìgbẹ́.
18 Amo esoha, Hina Gode da Ea ougi bagade hou olelesea, ilia silifa amola gouli gagui amo da ili hame gaga: mu. Osobo bagade huluane da Gode Ea ougi lalu agoane amoga wadela: lesi dagoi ba: mu. E da hedolodafa dunu huluane osobo bagade amoga esalebe, amo ilia esalusu dagolesimu.
Bẹ́ẹ̀ ni fàdákà tàbí wúrà wọn kì yóò sì le gbà wọ́n là ní ọjọ́ ìbínú Olúwa.” Ṣùgbọ́n gbogbo ayé ni a ó fi iná ìjowú rẹ̀ parun, nítorí òun yóò fi ìyára fi òpin sí gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilẹ̀ ayé.

< Sefanaia 1 >