< Segalaia 3 >

1 Na da esala ba: su eno ba: i. Amoga ba: loba, Hina Gode da nama gobele salasu Ouligisu dunu Yosiua, amo Hina Gode Ea a: igele ea midadi lelebe, amo nama olei. Amola Yosiua la: idi bega: dafulili Sa: ida: ne lelebe ba: i. Sa: ida: ne da Yosiuama diwaneya udidili sia: musa: momagele lelebe ba: i.
Ó sì fi Joṣua olórí àlùfáà hàn mí, ó dúró níwájú angẹli Olúwa, Satani sí dúró lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀ láti kọjú ìjà sí i.
2 Hina Gode Ea a: igele dunu da Sa: ida: nema agoane sia: i, “Sa: ida: ne! Hina Gode da dima diwaneya udidimu da defea. Hina Gode da Yelusalemema asigisa, amola E da dima diwaneya udidimu da defea. Goe dunu da ifa daba: laluga nemu gadenei, amoganini dale fasibi agoai ba: sa.”
Olúwa si wí fún Satani pé, “Olúwa bá ọ wí ìwọ Satani; àní Olúwa tí ó ti yan Jerusalẹmu, bá ọ wí, igi iná kọ́ ni èyí tí a mú kúrò nínú iná?”
3 Yosiua da amogai ledo bagade abula amo ga: ne lelebe ba: i.
A sì wọ Joṣua ni aṣọ èérí, ó sì dúró níwájú angẹli náà.
4 A: igele dunu da ea hadigi hawa: hamosu fidisu dunu ilima amane sia: i, “Amo dunu ea abula ledo bagade hamoi ga: i dialebe amo gisa: le fasima.” Amalu e da Yosiuama amane sia: i, “Na da dia wadela: i hou fadegale fasi dagoi. Amola na da dima abula gaheabolo ga: ma: ne imunu.”
Ó sì dáhùn ó wí fún àwọn tí ó dúró níwájú rẹ̀ pé, “Bọ́ aṣọ èérí nì kúrò ní ara rẹ̀.” Ó sì wí fún Joṣua pé, “Wò ó, mo mú kí àìṣedéédéé rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, èmi yóò sì wọ̀ ọ́ ní aṣọ ẹ̀yẹ.”
5 E da ea hadigi hawa: hamosu fidisu dunu ilima, Yosiua ea dialuma da: iya habuga fofoloi amo ligisima: ne sia: i. Ilia da amo defele hamoi. Amalu ilia da Yosiuama abula gaheabolo ga: sisi. Ilia da amo hamonanoba, Hina Gode Ea a: igele dunu da amogawi lelu.
Mó sì wí pé, “Jẹ kí wọn fi gèlè mímọ́ wé e lórí.” Wọn sì fi gèlè mímọ́ wé e lórí, wọn sì fi aṣọ wọ̀ ọ́. Angẹli Olúwa sì dúró tì í.
6 Amalalu, a:igele da Yosiuama amane sia: i,
Angẹli Olúwa sì tẹnumọ́ ọn fún Joṣua pé:
7 “Hina Gode Bagadedafa da amane sia: ba: , ‘Di da Na malasu nabawane hamosea, amola hawa: hamosu Na dima hamoma: ne sia: i amo hamosea, di da mae fisili gebewane Na Debolo Diasu amola ea gagoi sogebi amo ouligisu hou hamonanumu. Amola Na da a: igele dunu Na midadi esalebe amo ilia sia: ne gadosu nababe, amo defele Na da dia sia: ne gadosu nabimu.
“Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: ‘Bí ìwọ ọ́ bá rìn ní ọ̀nà mi, bí ìwọ yóò bá sì pa àṣẹ mi mọ́, ìwọ yóò sì ṣe ìdájọ́ ilé mi pẹ̀lú, ìwọ yóò sì ṣe àkóso ààfin mi, èmi yóò fún ọ ní ààyè láti rìn láàrín àwọn tí ó dúró yìí.
8 Yosiua! Di da gobele salasu Ouligisu dunu! Amaiba: le, noga: le nabima! Amola, dilia Yosiua amola gilisili gobele salasu hamosu dunu! Dilia da Isala: ili da fa: no hahawane ba: ma: ne, dawa: digisu olelesu agoane esala. Amaiba: le, dilia amola noga: le nabima! Na da Na hawa: hamosu dunu, Ea Dio amo da Ifa Amoda, amo dilima olemu.
“‘Gbọ́, ìwọ Joṣua olórí àlùfáà, ìwọ, àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ tí ó jókòó níwájú rẹ: nítorí ẹni ìyanu ni wọ́n: nítorí kíyèsi i, èmi yóò mú ẹ̀ka náà wá fun ìránṣẹ́ mi.
9 Na da Yosiua ea midadi amoga gele afadafa (amo gele da: iya da si fesuale gala) amo ligisimu. Na da amo gele da: iya faele dedemu. Amola eso afae fawane amoga, Na da Isala: ili soge ea wadela: i hou huluane fadegale fasimu.
Nítorí kíyèsi i, òkúta tí mo tí gbé kalẹ̀ níwájú Joṣua; lórí òkúta kan ni ojú méje wà: kíyèsi i, èmi yóò fín àkọlé rẹ̀,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ‘Èmi yóò sì mú ẹ̀bi ilẹ̀ náà kúrò ní ọjọ́ kan.
10 Amo eso da doaga: sea, dilia huluane afae afae da dilia na: iyado dunu misa: ne hiougimu. Ilia da misini, olofoiwane amola gaga: iwane, dilia waini sagai amola figi ifa bugi amoga sisiga: le disili, hahawane esalumu.”
“‘Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ní ọjọ́ náà ni olúkúlùkù yóò pe ẹnìkejì láti jókòó rẹ̀ sábẹ́ igi àjàrà àti sábẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́.’”

< Segalaia 3 >