< Segalaia 2 >

1 Na da esala ba: su eno amo ganodini, dunu amo ea loboga sedade defesu efe gagui dialebe ba: i.
Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀.
2 Na da ema adole ba: i, “Di da habi ahoa!” E da bu adole i, “Na da Yelusaleme defemusa: ahoa. Na da ea sedade amola ba: de amo defemusa: ahoa!”
Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?” O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”
3 Amalalu, na da ba: loba, a:igele dunu nama adolalu amo alia guda: lebe ba: i. Amola a: igele eno e gousa: musa: misi.
Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀.
4 Bisili misi a: igele dunu da eno a: igelema amane sia: i, “Hehenaia asili, ayeligi dunu defesu efe gagui ema amane sia: ma, ‘Yelusaleme moilai bai bagade amo ganodini, dunu amola bulamagau bagohamedafa ba: muba: le, moilai bai bagade gagomu da hamedei ba: mu.
Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀.
5 Hina Gode da amane ilegele sia: i dagoi. ‘Na Nisu fawane da laluga sisiga: le disi gagoi agoane moilai bai bagade fi gaga: ma: ne esalumu. Amola Na da hadigiwane amogai esalumu.’”
Olúwa wí pé: Èmi ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’
6 Hina Gode da Ea fi dunu ilima amane sia: i “Na da la: idi bega: la: idi bega: dilia huluane afagogolesi. Be dilia mugululi asi dunu! Waha dilia Ba: bilone soge yolesili, hobeale asili, Yelusalemega buhagima.
“Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá,” ni Olúwa wí, “nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.
7
“Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.”
8 Nowa da dili fasea, da Nama dogolegei liligi fasa.” Amaiba: le, Hina Gode Bagadedafa da fifi asi gala amo da Ea fi dunu ilia liligi doagala: le lai, ilima amo sia: sia: musa: , na asunasi,
Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀.
9 “Hina Gode Hisu da dilima gegemu. Amo dunu ilia da dilia hawa: hamosu dunu galu, ilia da dilia liligi doagala: le lamu.” Amane hamobe ba: sea, dunu huluane da Hina Gode Bagadedafa da na asunasi, amo dawa: mu.
Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.
10 Hina Gode da amane sia: i, “Yelusaleme dunu! Nodone gesami hea: ma! Na da dili bisili fifi lamusa: mana!”
“Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
11 Amo esoga, fifi asi gala bagohame da Hina Godema misini, Ea fidafa hamomu. E da dili bisili fifi lamu. Amasea, E da na dilima asunasi, amo dilia da dawa: digimu.
“Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi, èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ.
12 Bu enowane, Yuda da Hina Gode Ea dogolegei fi Ea sema soge amo ganodini ba: mu. Amola Yelusaleme da Ea baligili dogolegei moilai bai bagade ba: mu.
Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu.
13 Hina Gode Ea midadi, dunu huluane ouiya: ma! Bai E da Ea Hadigi fifi esalebe sogebi amoganini manebe!
Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”

< Segalaia 2 >