< Louma 9 >
1 Na da dafawane sia: sa! Na da Gelesu dunu. Amaiba: le, na da ogogosu hame dawa: Gode Ea A: silibu Hadigidafa da na asigi dawa: su amoma na da hame ogogosa sia: sa.
Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi kò ṣèké, ọkàn mi sì ń jẹ́ mi ní ẹ̀rí nínú Ẹ̀mí Mímọ́.
2 Na da da: i dioi bagade. Na dogo ganodini mae yolesili se naba.
Pé mo ní ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi.
3 Bai na da na osobo bagade fi dunu amo dawa: beba: le, se naba. Amo hou da na fi fidimu ganiaba, na da Godema gagabusu aligi amola Gelesu amoma afafae hame higala: loba.
Nítorí mo fẹ́rẹ lè gbàdúrà pé kí èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara.
4 Ilia da Gode Ea fi dunu esala. E da ili amo Ea mano hamone, Ea hadigi ili ba: ma: ne ilima olelei. E da ilima Ea gousa: su hou olelei amola ilima Sema i dagoi, Ilia da sia: ne gadosu houdafa dawa: Gode Ea hahawane dogolegele iasu ilegele sia: i liligi huluane da ilima doaga: i dagoi.
Àwọn ẹni tí i ṣe Israẹli; tí àwọn ẹni tí ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀mú, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí.
5 Ilia da musa: Hibulu siba fi dunu bagade amo ilia mano esala. Yesu Gelesu da osobo bagade dunu ea da: i hodo lale, ilia fi amo ganodini lalelegei. Gode da liligi huluane amoma ouligisuwane esalebeba: le, Ema eso huluane nodonanumu da defea. Ama. (aiōn )
Tí ẹni tí àwọn Baba í ṣe, àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí Kristi ti wá nípa ti ara, ẹni tí ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín. (aiōn )
6 Gode Ea fi dunuma hahawane dogolegele imunu ilegele sia: i, - amo da yolesi dagoi na da hame sia: sa. Isala: ili dunu mogili da Gode Ea fi dunu, mogili da Gode Ea fi dunu hame.
Ṣùgbọ́n kì í ṣe pé nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. Kì í sá í ṣe gbogbo àwọn tí ó ti inú Israẹli wá, àwọn ni Israẹli.
7 Amola A: ibalaha: me ea fi dunu mogili ilia da Gode Ea mano hame. Gode da A: ibalaha: mema amane sia: i, “Aisage ea mano lalelegesea, amo fawane da digaga manodafa fi Na da dima ilegele sia: i defele, esalumu.”
Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pé, nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. Ní ọ̀nà mìíràn, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
8 Bai agoane diala. Mano da osobo bagade dunu ilia hou defele lalelegesea da Gode Ea mano hame. Be Gode Ea hahawane dogolegele ilegele sia: beba: le lalelegei mano, ilia fawane da Gode Egaga fidafa.
Èyí nì ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a kà ní irú-ọmọ.
9 Gode da hahawane dogolegele iasu imunusa: amane ilegele sia: i, “Na eso ilegei amoga Na da bu masea, Sela da dunu mano lalelegemu.”
Nítorí ọ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: “Ní ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò wá, Sara yóò sì ní ọmọ ọkùnrin.”
10 Be amo fawane hame. Lebega ea dunu mano aduna da eda afadafa fawane esalu. Elea eda da ninia aowa Aisage esalu.
Kì í sì í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà tí Rebeka pẹ̀lú lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa.
Nítorí nígbà tí kò tí ì bí àwọn ọmọ náà, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tí ì ṣe rere tàbí búburú—kí ìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ kí ó lè dúró,
12 Be Gode da Hi fawane Ea mano ilegesa amo olelema: ne, E da Lebegama amane olelei, “Magobo mano da fa: no lalelegei mano amoma hawa: hamosu dunu agoane ba: mu.” Ela da mae lalelegele, wadela: i mae hamone, hou ida: i mae hamone, Gode da hidadea amo olelebeba: le, dunu ilia hawa: hamobeba: le hame, be Ea hanaiba: le fawane ilegesa, amo olelei.
kì í ṣe nípa ti iṣẹ́, bí kò ṣe ti ẹni tí ń peni—a ti sọ fún un pé, “Ẹ̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò.”
13 Amo defele Gode Sia: da agoane dedei diala, “Na Ya: igobema asigiba: le ilegei. Be Na da Iso hame hanaiba: le yolesi dagoi.
Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra.”
14 Amaiba: le Gode Ea hou da defele hame, moloi hame, amo ninia da sia: ma: bela: ? Hame mabu!
Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti wí? Àìṣòdodo ha wà lọ́dọ̀ Ọlọ́run bí? Kí a má ri!
15 Gode da Mousesema amane sia: i, “Nowa dunuma Na da gogolema: ne olofomusa: dawa: sea, Na da ea hou gogolema: ne olofomu. Nowa dunuma Na asigimu dawa: sea, Na da ema asigimu.”
Nítorí ó wí fún Mose pé, “Èmi ó ṣàánú fún ẹni tí èmi yóò ṣàánú fún, èmi yóò sì ṣe ìyọ́nú fún ẹni tí èmi yóò ṣe ìyọ́nú fún.”
16 Amaiba: le, hou huluane bai da dunu ilia hanaiba: le o hawa: hamobeba: le hame, be bai da Gode Ea hanaiba: le gogolema: ne olofosu hou fawane ba: sa.
Ǹjẹ́ bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe ti ẹni tí ó fẹ́, kì í sì í ṣe ti ẹni tí ń sáré, bí kò ṣe ti Ọlọ́run tí ń ṣàánú.
17 Gode Sia: da agoane dedei diala, “Gode da Idibidi Ouligisu dunuma amane sia: i, ‘Na gasa olelema: ne amola osobo bagade fifi asi gala dunu huluane Na hou dawa: ma: ne, Na da di Idibidi ouligisu ilegei dagoi!’”
Nítorí ìwé mímọ́ wí fún Farao pé, “Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé ọ dìde, kí èmi kí ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti kí a bá à le máa ròyìn orúkọ mi ká gbogbo ayé.”
18 Amaiba: le, Gode da nowa dunuma olofosu imunusa: dawa: sea, E da amo dunuma olofosu iaha. Amola nowa dunu ea dogo E da igiwane hamomusa: dawa: sea, E da amo dunu ea dogo igiwane hamosa.
Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni tí ó wù ú, ẹni tí ó wù ú a sì mú ní ọkàn le.
19 Be dunu afae da nama agoane adole ba: mu, “Gode da agoane hamoi dagoiba: le, e da abuliba: le osobo bagade dunuma fofada: sala: ? Gode Ea hanai hou afadenemu da ninima hamedei galebe.”
Ìwọ ó sì wí fún mi pé, “Kín ni ó ha tún bá ni wí sí? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́nà?”
20 Be agoane sia: mu galea, na da bu adole imunu, “Na: iyado! Di da Godema bu gagabole sia: mu da hamedei. Ofodo amo da laga osoboga hamoi, da amo ofodo hahamosu dunuma bu gagabole amane sia: mu, “Dia da abuliba: le na agoane hamobela: ? amo sia: mu da hamedei!” na amane adole imunu.
Bẹ́ẹ̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, tà ni ìwọ tí ń dá Ọlọ́run lóhùn? “Ohun tí a mọ, a ha máa wí fún ẹni tí ó mọ ọ́n pé, ‘Èéṣe tí ìwọ fi mọ mi báyìí?’”
21 Ofodo hahamosu dunu, hi fawane da ea hanai defele osobo hamone, ofodo hisu hisu hamomu da defea. E da ofodo afadafa eso bagade lolo nabe eso agoane ganodini ha: i manu ligisimusa: hisu hamosa, eno da eso fonobahadi ganodini ha: i manu ligisimusa: hisu hamomu da defea.
Amọ̀kòkò kò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò sí ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò sí àìlọ́lá?
22 Gode Ea hou hamoi da amo defele diala. E da wadela: i hou amoga Ea ougi hou amola Ea gasa bagade hou, amo olelemusa: dawa: i. Be E da dunu hobea Ea wadela: ma: ne fofada: su ba: mu dunu, ilima E da hedolo hame se dabe iasu i.
Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? Tí ó sì fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mí mọ̀, tí ó sì mú sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú tí a ṣe fún ìparun.
23 Eno amola E da Ea baligiliwane hadigi hou olelemusa: dawa: i. Amo hou E da nini (Ea gogolema: ne olofosu lai dagoi dunu, Ea hadigi lama: ne E da hahamoi) ninima Ea hadigi hou E da baligiliwane i dagoi.
Àti kí ó lè sọ ọ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mí mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú tí ó ti pèsè ṣáájú fún ògo.
24 Gode da Yu dunuma fawane hame wele sia: su, be Dienadaile dunu amola ilima wele sia: i dagoi. Ninia da amo fi diala.
Àní àwa, tí ó ti pè, kì í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀lú?
25 Gode da Hosia meloa ganodini agoane sia: sa, “Musa: fi dunu amo da Na fi dunu hame Na sia: i. Be Na da hobea amo fi dunu da Na fi dunu sia: mu. Fi dunu da musa: Na da ilima hame asigi, amo fi dunuma Na da amane sia: mu, ‘Dilia da Na dogolegei fi!’
Bí ó ti wí pẹ̀lú ní Hosea pé, “Èmi ó pe àwọn tí kì í ṣe ènìyàn mi, ní ‘ènìyàn mi’, àti ẹni tí kí í ṣe àyànfẹ́ ní ‘àyànfẹ́.’”
26 Amola sogebi amo ganodini Na da musa: ilima sia: i, ‘Dilia da Na fi dunu hame!’ amo sogebi ganodini Na da ilima amane sia: mu, ‘Dilia da Esalebe Gode Ea mano!’
Yóò sì ṣe, “Ní ibi ti a gbé ti sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó gbé pè wọ́n ní ‘ọmọ Ọlọ́run alààyè.’”
27 Gode Sia: eno da agoane dedei diala. Aisaia da Isala: ili dunu ilia hou olelemusa: amane sia: sa, “Isala: ili dunu ilia idi da sa: i amo hano bagade bega: diala, amo ea idi defele gala ba: sa ganiaba, bagahame fawane da Gode Ea gaga: su hou ba: mu.
Isaiah sì kígbe nítorí Israẹli pé: “Bí iye àwọn ọmọ Israẹli bá rí bí iyanrìn Òkun, apá kan ni ó gbàlà.
28 Bai Gode Ea wadela: ma: ne fofada: su da osobo bagadega hedolowane doaga: mu!”
Nítorí Olúwa yóò mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé, yóò parí rẹ̀, yóò sì ké e kúrò ní òdodo.”
29 Amola Aisaia da Isala: ili fi ilia hou dawa: beba: le, amane sia: i, “Hina Gode Bagadedafa da ninigaga fi ganodini afae afae hame fane legei ganiaba, ninia da Sodame moilai fi amola Goumola moilai fi, agoaiwane ba: la: loba.”
Àti bí Isaiah ti wí tẹ́lẹ̀: “Bí kò ṣe bí Olúwa àwọn Ọmọ-ogun ti fi irú-ọmọ sílẹ̀ fún wa, àwa ìbá ti dàbí Sodomu, a bá sì ti sọ wá dàbí Gomorra.”
30 Amaiba: le, ninia agoane dawa: Dienadaile dunu da Gode ba: ma: ne, ilia hou afadenei moloidafa hamoi, amo ba: ma: ne logo hame hogoi. Be ilia Gode Ea hou dafawaneyale dawa: beba: le, ilia afadenene bu moloidafa hamoi ba: i dagoi
Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèfèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.
31 Be Gode Ea fidafa dunu da sema hamobeba: le, ilia da Gode da ili hahawane moloidafa hamoi dagoi dawa: i galu. Be amo logo hogoi helele, hame ba: i.
Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn kò tẹ òfin òdodo.
32 Ilia dafawaneyale dawa: su hou mae dawa: le, be ilisu hawa: hamobe amo dawa: beba: le, logo hame ba: i. Amaiba: le fedege agoane, ilia igi amoga emo udagagubiba: le, dafai.
Nítorí kí ni? Nítorí wọn kò wá a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n bí ẹni pé nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni.
33 Amo igi ea hou olelema: ne, Gode Sia: da amane dedei diala, “Ba: ma! Na da dunu ilia emo udagaguli dafama: ne, Saione moilai amo ganodini igi ligisimu. Dunu da amo igiga dafamu. Be nowa dunu da Gode Ea hou dafawaneyale dawa: sea, amo da hamedafa gogosiamu.”
Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Kíyèsi, mo gbé òkúta ìkọ̀sẹ̀ kalẹ̀ ní Sioni àti àpáta tí ó mú wọn ṣubú, ẹnikẹ́ni ti ó bá sì gbà a gbọ́, ojú kì yóò tì í.”