< Wamolegei Sia: Olelesu 18 >

1 Amalalu, na da a: igele dunu Hebene soge yolesili, osoboga manebe ba: i. E da hina bagade agoane ba: i. Ea hadigi da osobo bagade huluane hadigi hamoi.
Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí mo sì rí angẹli mìíràn, ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá ti òun ti agbára ńlá; ilẹ̀ ayé sì ti ipa ògo rẹ̀ mọ́lẹ̀.
2 E da ha: giwane wele sia: i, “Uda da dafai dagoi. Ba: bilone Bagade da dafai dagoi. Fio liligi amola nigima: a:silibu, amo fawane amo moilai bai bagade ganodini esala. Wadela: i ledo bagade sio fi hisu hisu da amo moilai bai bagade ganodini esala.
Ó sì kígbe ní ohùn rara, wí pé: “Babeli ńlá ṣubú! Ó ṣubú! Ó sì di ibùjókòó àwọn ẹ̀mí èṣù, àti ihò fún ẹ̀mí àìmọ́ gbogbo, àti ilé fún ẹyẹ àìmọ́ gbogbo, ilé fún ẹranko ìríra àti àìmọ́ gbogbo.
3 Bai dunu fifi asi gala huluane da fedege agoane amo ea wadela: i hanai hou gasa bagade waini hano mai dagoi. Osobo bagade ouligisu dunu da ema wadela: i uda lasu hou hamosu amola osobo bagade bidi lasu dunu da e gasa bagade wadela: i hou hanaiwane hamobeba: le, muni bagade lai.”
Nítorí nípa ọtí wáìnì ìrunú àgbèrè rẹ̀ ni gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ṣubú. Àwọn ọba ayé sì ti bá a ṣe àgbèrè, àti àwọn oníṣòwò ayé sì di ọlọ́rọ̀ nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọ̀bìà rẹ̀.”
4 Amalalu, na da sia: eno muagadodi misi amane nabi, “Na fi dunu! Ba: bilone moilai bai bagade yolesili, misa! Dilia da ea wadela: i hou gilisili mae hamoma! Dilia da ea se dabe iasu gilisili ba: mu da defea hame.
Mo sì gbọ́ ohùn mìíràn láti ọ̀run wá, wí pé: “‘Ẹ ti inú rẹ̀ jáde, ẹ̀yin ènìyàn mi,’ kí ẹ ma bá a ṣe alábápín nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí ẹ ma bà á sì ṣe gbà nínú ìyọnu rẹ̀.
5 Bai ea wadela: i hou da gilisibiba: le, afae da afae da: iya ligisiba: le, Hebene sogega doaga: i. Gode da ea wadela: i hou hame gogolei.
Nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ga títí dé ọ̀run, Ọlọ́run sì ti rántí àìṣedéédéé rẹ̀.
6 Ema dabema amola ea afadafa wadela: i hou hamoi galea, ema se dabe iasu amo defele aduna ima. E da se nabasu bagade iabeba: le, ema gasa bagadedafa baligiliwane dabe ima.
San an fún un, àní bí òun tí san án fún ní, kí ó sì ṣe e ni ìlọ́po méjì fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀, nínú ago náà tí o ti kún, òun ni kí ẹ sì kún fún un ni méjì.
7 E da hadigi amola liligi ida: iwane hi hanai liligi labeba: le, ema se nabasu amola da: i dioi, amo defele imunu da defea. Bai e da wali udigili amane sia: sa, “Na da didalo hame! Na da hina bagade uda agoane fi esala. Na da se nabasu hamedafa ba: mu!”
Níwọ́n bí o ti yin ara rẹ̀ lógo tó, tí ó sì hùwà wọ̀bìà, níwọ̀n bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ dá a lóró kí ẹ sì fún un ní ìbànújẹ́; nítorí tí ó wí ní ọkàn rẹ̀ pé, ‘Mo jókòó bí ọbabìnrin, èmi kì sì í ṣe opó, èmí kì yóò sì rí ìbànújẹ́ láé.’
8 Amaiba: le, eso afadafa ganodini e da se bagade nabimu. Olosu, da: i dioi amola ha: su da ema doaga: mu. E da laluga nemu.
Nítorí náà, ní ọjọ́ kan ni ìyọnu rẹ̀ yóò dé, ikú, àti ìbìnújẹ́, àti ìyàn; a ó sì fi iná sun ún pátápátá: nítorí pé alágbára ni Olúwa Ọlọ́run tí ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
9 Osobo bagade hina bagade dunu amo da e amola gilisili wadela: le hamosu, ilia da amo moilai bai bagade laluga nenanebe ba: sea, bagadewane dimu.
“Àti àwọn ọba ayé, tí ó ti ń bá a ṣe àgbèrè, tiwọn sì ń hùwà wọ̀bìà, yóò sì pohùnréré ẹkún lé e lórí, nígbà tí wọn bá wo èéfín ìjóná rẹ̀.
10 Ilia da gilisili e se nabasu lasa: besa: le, sedagawane ba: lalawane lelumu. Ilia da amane sia: mu, “Ameia: ! Ameia: ! Ba: bilone bagade, moilai bai bagade ida: iwane galu. Eso afadafa ganodini di da se dabe iasu lai dagoiba: le dafai!”
Wọ́n ó dúró ní òkèrè réré nítorí ìbẹ̀rù iṣẹ́ oró rẹ̀, wọn ó máa wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá náà, Babeli ìlú alágbára nì! Nítorí ní wákàtí kan ni ìdájọ́ rẹ dé!’
11 Osobo bagade bidi lasu dunu amola da e dawa: le, dimu amola didiga: mu. Bai wali eno dunu da ilia liligi bu hame bidi laha.
“Àwọn oníṣòwò ayé sì ń sọkún, wọn sì ń ṣọ̀fọ̀ lórí rẹ̀, nítorí pé ẹnikẹ́ni kò rà ọjà wọn mọ́.
12 Liligi huluane amo gouli, silifa, igi ida: iwane, su amola abula ida: iwane, liligi ida: iwane ifa, igi, ouli amola balase, amoga hamoi liligi,
Ọjà wúrà, àti ti fàdákà, àti ti òkúta iyebíye, àti ti perli, àti ti aṣọ ọ̀gbọ̀ wíwẹ́, àti tí elése àlùkò, àti ti ṣẹ́dà, àti ti òdòdó, àti ti gbogbo igi olóòórùn dídùn, àti ti olúkúlùkù ohun èlò tí a fi igi iyebíye ṣe, àti ti idẹ, àti ti irin, àti ti òkúta mabu.
13 sinamone, hedama: ne fodole nasu liligi, gabusiga: manoma, fala: gisenese, waini hano, falaua, widi, bulamagau, sibi, hosi, sa: liode amola udigili hawa: hamosu dunu, amo huluane dunu eno da bu hame bidi lamuba: le, ilia da disa.
Àti ti Kinamoni, àti ti onírúurú ohun olóòórùn dídùn, àti ti ohun ìkunra, àti tí tùràrí, àti ti ọtí wáìnì, àti ti òróró, àti ti ìyẹ̀fun dáradára, àti ti alikama, àti ti ẹran ńlá, àti ti àgùntàn, àti ti ẹṣin, àti ti kẹ̀kẹ́, àti ti ẹrú, àti ti ọkàn ènìyàn.
14 Bidi lasu dunu da Ba: bilone amoma amane sia: sa, “Liligi ida: iwane gala di da lalegagumu hanai galu, amo da mugululi asi. Dia gagui amola ida: iwane ba: su da asi dagoi. Di da amo bu hamedafa ba: mu!”
“Àti àwọn èso tí ọkàn rẹ̀ ń ṣe. Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí, si lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ, àti ohun gbogbo tí ó dùn tí ó sì dára ṣègbé mọ́ ọ lójú, kì yóò sì tún rí wọn mọ́ láé.
15 Bidi lasu dunu, (amo da amo moilai bai bagadega bidi lasu hawa: hamobeba: le bagade gagui), ilia da ea se nabasu gilisili ba: sa: besa: le, sedagawane lelumu. Ilia da dimu amola didiga: mu.
Àwọn oníṣòwò nǹkan wọ̀nyí, tí a ti ipa rẹ̀ sọ di ọlọ́rọ̀, yóò dúró ní òkèrè réré nítorí ìbẹ̀rù iṣẹ́ oró rẹ̀, wọn o máa sọkún, wọ́n ó sì máa ṣọ̀fọ̀,
16 Ilia da amane sia: mu, “Ameia: ! Ameia: ! Moilai bai bagade da se bagade nabi. E da musa: abula ida: iwane amo yoi, oga: iyei amola gouli liligi amo lasu amola gifalo amoga sali.
wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá nì, tí a wọ̀ ní aṣọ ọ̀gbọ̀ wíwẹ́, àti ti elése àlùkò, àti ti òdòdó, àti ti a sì fi wúrà ṣe ní ọ̀ṣọ́, pẹ̀lú òkúta iyebíye àti peali!
17 Be hedolodafa (aua afae agoane) e da amo liligi huluane yolesi dagoi. Dusagai ouligisu dunu, genonesisu dunu, dunu ilia amo ganodini ahoa amola dunu huluane ilia hano wayabo bagade amoga hawa: hamonanebeba: le esaloma: ne liligi laha, amo da sedagawane lelu,
Nítorí pé ní wákàtí kan ni ọrọ̀ ti o pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ di asán!’ “Àti olúkúlùkù ẹni tí ń rin ojú omi lọ sí ibikíbi, àti àwọn ti ń ṣiṣẹ́ nínú ọkọ àwọn ti ń ṣòwò ojú Òkun dúró ní òkèrè réré,
18 Ba: bilone nenanebeba: le lalu amola mobi, heda: lebe ba: loba, ilia amane wele sia: i, “Moilai bai bagade eno amo moilai bai bagade agoane da hamedafa ba: su.”
wọ́n sì kígbe nígbà tí wọ́n rí èéfín jíjóná rẹ́, wí pé, ‘Ìlú wo ni o dàbí ìlú yìí?’
19 Ilia da osobo gasa: le, ilisu dialuma da: iya ligisili, amane wele sia: i, “Ameia: ! Ba: bilone da se bagade nabi. Amo moilai bai bagade ganodini, dusagai hawa: hamosu dunu da muni bagade ba: i. Be hedolodafa (aua afae amoga) e da ea gagui huluane fisi dagoi!”
Wọ́n sì kú ekuru sí orí wọn, wọ́n kígbe, wọ́n sọkún, wọn sì ń ṣọ̀fọ̀, wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá náà, nínú èyí tí a sọ gbogbo àwọn tí ó ni ọkọ̀ ní Òkun di ọlọ́rọ̀ nípa ohun iyebíye rẹ̀! Nítorí pé ni wákàtí kan, a sọ ọ́ di ahoro.’
20 Hebene ganodini fi! E da gugunufinisi dagoiba: le, hahawane nodoma! Gode Ea fi dunu, asunasi dunu amola balofede dunu! Dilia nodoma! Bai Ba: bilone da dilima wadela: le hamobeba: le, Gode da ema dabe i dagoi.
“Yọ̀ lórí rẹ̀, ìwọ ọ̀run! Ẹ yọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Ọlọ́run! Ẹ yọ̀, ẹ̀yin aposteli mímọ́ àti wòlíì! Nítorí Ọlọ́run ti gbẹ̀san yín lára rẹ̀ nítorí ìdájọ́ tí ó gbé ka orí rẹ.”
21 Amalalu, a:igele gasa bagade amo da igi bagade gaguia gadole, hano wayabo bagade amoga sanasi. E amane sia: i, “Ba: bilone da amaiwane sanasili, bu hamedafa ba: mu.
Angẹli alágbára kan sì gbé òkúta kan sókè, ó dàbí ọlọ ńlá, ó sì jù ú sínú Òkun, wí pé: “Báyìí ní a ó fi agbára ńlá bí i Babeli ìlú ńlá ni wó, a kì yóò sì rí i mọ́ láé.
22 Amo moilai bai bagade ganodini, sani baidama dubi, dunu ilia gesami, faludi amola dalabede fulaboi, amo da bu hamedafa nabimu. Hawa: hamosu dunu da di ganodini bidi lasu hawa: bu hame hamomu. Widi goudasu igi da udigili dialebeba: le, bu hame nabimu galebe.
Àti ohùn àwọn aludùùrù, àti ti àwọn olórin, àti ti àwọn afunfèrè, àti ti àwọn afùnpè, ni a kì yóò sì gbọ́ nínú rẹ mọ́ rara; àti olúkúlùkù oníṣọ̀nà ohunkóhun ni a kì yóò sì rí nínú rẹ mọ́ láé. Àti ìró ọlọ ní a kì yóò sì gbọ́ mọ̀ nínú rẹ láé;
23 Di ganodini gamali nenanebe bu hame ba: mu. Udalai dunu amola uda, ela gilisili sia: dabe bu hame nabimu. Dia bidi lasu hawa: hamosu dunu ilia da gasa bagadeba: le, eno osobo bagade bidi lasu hawa: hamosu dunu ili baligi dagoi. Dia ogogosu sema nabi hou amoga di da osobo bagade fifi asi gala dunu huluane ogogoi.
Àti ìmọ́lẹ̀ fìtílà ni kì yóò sì tàn nínú rẹ̀ mọ́ láé; a kì yóò sì gbọ́ ohùn ọkọ ìyàwó àti ti ìyàwó nínú rẹ mọ́ láé: nítorí pé àwọn oníṣòwò rẹ̀ ni àwọn ẹni ńlá ayé; nítorí pé nípa ọ̀ṣọ́ rẹ̀ ní a fi tàn orílẹ̀-èdè gbogbo jẹ.
24 Gode da Ea fi dunu amola balofede dunu, amo ilia maga: me Ba: bilone moilai bai bagade ganodini dialebe ba: beba: le, Ba: bilone da se dabe iasu lai. Dafawane! Dunu huluane osobo bagadega enoga medole legei, amo ilia maga: me da Ba: bilone moilai bai bagade ganodini dialebe ba: i.”
Àti nínú rẹ̀ ní a gbé ri ẹ̀jẹ̀ àwọn wòlíì, àti ti àwọn ènìyàn mímọ́, àti ti gbogbo àwọn tí a pa lórí ilẹ̀ ayé.”

< Wamolegei Sia: Olelesu 18 >