< Gesami Hea:su 39 >

1 Na da amane sia: i, “Na da dawa: iwane hamomu. Na da na gona: su amoga mae wadela: le hamoma: mu. Wadela: i hamosu dunu da na gadenene aligisia, na da sia: hamedafa sia: mu.”
Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Saamu Dafidi. Mo wí pé, “Èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi kí èmi kí ó má fi ahọ́n mi ṣẹ̀; èmi yóò fi ìjánu kó ara mi ní ẹnu níwọ̀n ìgbà tí ènìyàn búburú bá ń bẹ ní iwájú mi.”
2 Na da ouiya: le esalu. Noga: i hou amolawane, na da hamedafa sia: i. Be na da bu baligiliwane se nabi.
Mo fi ìdákẹ́ ya odi; mo tilẹ̀ pa ẹnu mi mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ rere; ìbànújẹ́ mi sì pọ̀ sí i.
3 Amalalu, beda: su hou da na hasali dagoi. Na da bu dawa: lalu amola bu baligili beda: i galu. Na da adole ba: su ouiya: mu da hamedei. Na da Hina Godema amane adole ba: i,
Àyà mi gbóná ní inú mi. Nígbà tí mo ń ṣàṣàrò, iná ràn; nígbà náà ni mo fi ahọ́n mi sọ̀rọ̀:
4 “Hina Gode! Na da habowali seda esaloma: bela: ? Na da habogala bogoma: bela: ? Nama adoma! Na esalusu da habogala dagoma: bela: ?”
“Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi, àti ìwọ̀n ọjọ́ mi, bí ó ti rí kí èmi kí o le mọ ìgbà tí mó ní níhìn-ín.
5 Di da nama esalusu dunumuni fawane i dagoi. Na esalusu da Dia siga hamedei agoane ba: sa. Dafawane! Esalebe dunu huluane afae afae ea esalusu da foga afae fulabole fasibi defele gala.
Ìwọ ti ṣe ayé mi bí ìbú àtẹ́lẹwọ́, ọjọ́ orí mi sì dàbí asán ní iwájú rẹ. Dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn nínú ìjókòó rere rẹ̀ jásí asán pátápátá. (Sela)
6 Ea esalusu da baba ba: be defele amola seda hame gala. Ea hamobe huluane da udigili fawane hamosa. E da muni amola liligi gagadosa. Be amo fa: no lamu dunu e da hame dawa:
“Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji. Nítòótọ́ ni wọ́n ń yọ ara wọn lẹ́nu lórí asán; wọ́n ń kó ọrọ̀ jọ, wọn kò sì mọ ẹni tí yóò ko lọ.
7 Hina Gode! Amai galea, na da adi dafawane hamoma: beyale dawa: ma: bela: ? Na dafawane hamoma: beyale dawa: su da Dima dawa: lumu.
“Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí, Olúwa, kín ni mo ń dúró dè? Ìrètí mí ń bẹ ní ọ̀dọ̀ rẹ.
8 Na wadela: i hou hamoi huluane, amoga Dia na gaga: ma. Amola gagaoui dunu ilia naba: le mae oufesega: ma: ma.
Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo. Kí o má sì sọ mí di ẹni ẹ̀gàn àwọn ènìyàn búburú.
9 Na da ouiya: i dialumu, na da sia: afae hame sia: mu. Bai na agoane se nabima: ne, Difawane agoane hahamonesi.
Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́; èmi kò sì ya ẹnu mi, nítorí wí pé ìwọ ni ó ṣe é.
10 Di da nama dawa: ma: ne olelesu se iasu bu mae ima! Na da Dia fane sali amoga bogomu agoai galebe.
Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi; èmí ṣègbé tán nípa lílù ọwọ́ rẹ.
11 Dunu ilia da wadela: i hou galea fawane, Di da ilima se bidi iaha. Amola Di da aowaba agoane, ilia liligi amoga ilia da asigi amo wadela: lesisa. Dafawane! Osobo bagade dunu da foga afae fulabolesibi amo defele gala.
Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀ fún ènìyàn nítorí ẹ̀ṣẹ̀, ìwọ a mú ẹwà rẹ parun bí kòkòrò aṣọ; nítòótọ́ asán ni ènìyàn gbogbo.
12 Hina Gode! Na Dima sia: ne gadobe nabima! amola na Dima dini iabe nabima! Na da dinanea, nama fidila misa! Na da na aowalali defele, wahamusu dima sofe misi esala.
“Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa, kí o sì fetí sí igbe mi; kí o má ṣe di etí rẹ sí ẹkún mi. Nítorí àlejò ni èmi lọ́dọ̀ rẹ, àti àtìpó, bí gbogbo àwọn baba mi ti rí.
13 Na da hedolowane asili, bu hame ba: muba: le, Dia na fonobahadi hahawane hamoma: ne, na yolesima.
Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára, kí èmi tó lọ kúrò níhìn-ín yìí, àti kí èmi ó tó ṣe aláìsí.”

< Gesami Hea:su 39 >