< Gesami Hea:su 38 >

1 Hina Gode! Dia ougiba: le, nama se bidi mae ima!
Saamu Dafidi. Ẹ̀bẹ̀. Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni kí o má ṣe fi ìyà jẹ mí nínú ìrunú rẹ̀.
2 Di da na Dia dadi amoga fa: ginisi, amola na fane sanasi.
Nítorí tí ọfà rẹ kàn mọ́ mi ṣinṣin, ọwọ́ rẹ sì kì mí mọ́lẹ̀.
3 Dia da nama ougiba: le, na se baligili nabala. Na wadela: i hou hamobeba: le, na da: i huluane da olo bagade madelasa.
Kò sí ibi yíyè ní ara à mi, nítorí ìbínú rẹ; kò sí àlàáfíà nínú egungun mi nítorí i ẹ̀ṣẹ̀ mi.
4 Na da nina: wadela: i hamonana fedege agoane hano heda: i amoga gela daha. Na wadela: i hou da fedege agoane, liligi bagadedafa aguni masunu hamedei agoai ba: sa.
Nítorí àìṣedéédéé mi ti borí mi mọ́lẹ̀; wọ́n tó ìwọ̀n bi àjàgà tí ó wúwo jù fún mi.
5 Bai na da gagaoule hamobeba: le, na aiya da dasale gahasa.
Ọgbẹ́ mi ń rùn ó sì díbàjẹ́ nítorí òmùgọ̀ mi.
6 Na da se nabawane beguduli, gala: la sa: i. Na da hahabe asili daeya, mae fisili, dinana.
Èmi ń jòwèrè, orí mi tẹ̀ ba gidigidi èmi ń ṣọ̀fọ̀ rìn kiri ní gbogbo ọjọ́.
7 Na da asugiba: le, da: i goaeasa. Amola na da bogomu gadenei ba: sa.
Nítorí ẹ̀gbẹ́ mi kún fún ìgbóná tí ń jóni kò sì ṣí ibi yíyè ní ara mi.
8 Na da gasa hamedene, dafawane gala: la sa: i. Na da da: i dioi, amola se nababeba: le gayasa.
Ara mi hù, a sì wó mi jẹ́gẹjẹ̀gẹ; mo kérora nítorí ìrúkèrúdò àyà mi.
9 Hina Gode! Na hanai amo Dia dawa: ! Na gayabe huluane Dia naba!
Olúwa, gbogbo ìfẹ́ mi ń bẹ níwájú rẹ; ìmí ẹ̀dùn mi kò sá pamọ́ fún ọ.
10 Na habe da ha: ha: sa, amola na gasa da asi dagoi. Na si da mobi sa: i dagoi.
Àyà mi ń mí hẹlẹ, agbára mi yẹ̀ mí sílẹ̀; bí ó ṣe ti ìmọ́lẹ̀ ojú mi ni, ó ti lọ kúrò lára mi.
11 Na da aiya bagohame madelaiba: le, na sama amola na na: iyado fi dunu ilia da nama hame gadenena maha. Na sosogodafa amolalia na hagasa.
Àwọn ọ̀rẹ́ mi àti àwọn ẹlẹgbẹ́ mi dúró lókèèrè réré kúrò níbi ìpọ́njú mi, àwọn alábágbé mi, dúró lókèèrè.
12 Dunu da na medole legemusa: dawa: be, ilia da na sa: ima: ne sanenisa. Amola dunu da nama se ima: ne dawa: be, ilia da na wadela: lesimusa: magagisa. Ilia da na wadela: lesimusa: sia: fane ilegesu hou hame yolesisa.
Àwọn tí n wá ẹ̀mí mi dẹ okùn sílẹ̀ fún mi; àti àwọn tí ó fẹ́ pa mí lára ń sọ̀rọ̀ nípa ìparun, wọ́n sì ń gbèrò ẹ̀tàn ní gbogbo ọjọ́.
13 Na da ge ga: i dunu defele, hame naba. Amola na da sia: hamedei dunu agoane, hame sia: da.
Ṣùgbọ́n mo dàbí adití odi, èmi kò gbọ́ ọ̀rọ̀; àti bí odi, tí kò le sọ̀rọ̀.
14 Na da ge ga: iba: le, dabe adole imunu hamedei dunu agoai gala.
Nítòótọ́, mo rí bí ọkùnrin tí kò gbọ́rọ̀, àti bí ẹnu ẹni tí kò sí ìjiyàn.
15 Hina Gode, na da dima dafawaneyale dawa: sa, amola Di da na Hina Godeba: le, nama dabe adole imunu.
Ṣùgbọ́n sí ọ Olúwa, ìwọ ni mo dúró dè; ìwọ ni, Olúwa Ọlọ́run mi, ẹni tí yóò dáhùn.
16 Na da se nabasu baligilidafa nababeba: le, nama ha lai dunu da na mae habosesema: ma. Ilia da na dafai hou ba: beba: le, Dia mae habosesele sia: ma: ma!
Nítorí tí mo gbàdúrà, “Gbóhùn mi, kí wọn má ba à yọ̀ mí; nígbà tí ẹsẹ̀ mi bá yọ̀ wọn yóò máa gbé ara wọn ga sí mi.”
17 Na da maedafa fisili, se naba. Amola na da dafamu gadenei ba: sa.
Nítorí tí mo ti ṣetán láti ṣubú, ìrora mi sì wà pẹ̀lú mi nígbà gbogbo.
18 Na da na wadela: i hou sisane fofada: sa. Be na da amo dawa: beba: le, bagadewane beda: sa.
Mo jẹ́wọ́ ìrékọjá mi; àánú sì ṣe mí fún ẹ̀ṣẹ̀ mi.
19 Na ha lai dunu da dagumui noga: i amola gasa fi gala. Nama ha lai dunu bagohame da nama bai hamedene, higale ba: sa.
Àwọn tí ó jẹ́ ọ̀tá mi láìnídìí pàtàkì, wọ́n lágbára púpọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn tí ó kórìíra mi lọ́nà òdì.
20 Dunu amo da noga: le hamobe dunuma wadela: i dabe iaha, ilia da na higale ba: sa. Bai na da moloi hou amoga hamomusa: , logo hogobeba: le.
Àwọn tí wọn ń fi ibi san rere fún mi àwọn ni ọ̀tá mi nítorí pé mò ń tọ ìre lẹ́yìn.
21 Hina Gode! Dia na mae fisiagama! Na Gode! Nama gasigale mae aligima!
Má ṣe kọ̀ mí sílẹ̀, ìwọ Olúwa! Ọlọ́run mi, má ṣe jìnnà sí mi.
22 Hina Gode! Na Gaga: sudafa! Wahadafa, na fidima!
Yára láti ràn mí lọ́wọ́, Olúwa, Olùgbàlà mi.

< Gesami Hea:su 38 >