< Gesami Hea:su 105 >
1 Hina Godema nodone sia: ma! Ea gasa bagade hou olelema! Ea hamobe amo fifi asi gala huluanema olelema!
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀, jẹ́ kí a mọ ohun tí ó ṣe láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.
2 Hina Godema nodone gesami hea: le ima! Amola liligi noga: idafa Ea hamobe amo adodoma.
Kọrin sí i, kọrin ìyìn sí i; sọ ti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ gbogbo.
3 Nini da Ea fi dunuba: le, hahawane nodoma. Amola dunu huluane Ema nodone sia: ne gadobe amo da hahawane nodoma: ma.
Ṣògo nínú orúkọ mímọ́ rẹ̀, jẹ́ kí ọkàn àwọn tí ń wá Olúwa kí ó yọ̀.
4 Hina Gode Ea fidima: ne lala masa, amola Ema mae yolele nodonanoma!
Wá Olúwa àti ipá rẹ̀; wa ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.
5 Dilia da Gode Ea hawa: hamosu dunu A: ibalaha: me amola Ya: igobe, Hi ilegele lai, egaga fifi mana. Dilia da Gode Ea musa: degabo hame ba: su hou hamoi amo dawa: ma, amola se imunusa: fofada: su Ea hamoi, amo bu dawa: ma.
Rántí àwọn ìyanu tí ó ti ṣe, ìyanu rẹ̀, àti ìdájọ́ tí ó sọ,
ẹ̀yin ìran Abrahamu ìránṣẹ́ rẹ̀, ẹ̀yin ọmọkùnrin Jakọbu, àyànfẹ́ rẹ̀.
7 Hina Gode da ninia Gode. Ea hamoma: ne sia: i, E da osobo bagade fifi asi huluane ilima sia: i.
Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa: ìdájọ́ rẹ̀ wà ní gbogbo ayé.
8 E da Ea Gousa: su sema hamoi amo eso huluane mae fisili ouligilalumu. E hamomusa: ilegei da fifi manebe 1,000 bobaligila masunu, ilima dialumu.
Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé, ọ̀rọ̀ tí ó pàṣẹ, fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran,
9 E da A: ibalaha: me amola Aisage elama hamomusa: ilegele sia: i, amo E da gagui dialumu.
májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu, ìbúra tí ó ṣe pẹ̀lú fún Isaaki.
10 Hina Gode da Ya: igobema eso huluane dialoma: ne gousa: su hamoi.
Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu gẹ́gẹ́ bí àṣẹ, sí Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú ayérayé:
11 E amane ilegele sia: i, “Na da Ga: ina: ne soge dima imunu. Amo soge da di fawane gaguli esalumu.”
“Fún ìwọ ni èmi ó fún ní ilẹ̀ Kenaani gẹ́gẹ́ bí ìpín tí ìwọ ó jogún.”
12 Gode Ea fi dunu da bagahame galu. Ilia da Ga: ina: ne soge ganodini ga fi dunu agoane ba: i.
Nígbà tí wọn kéré níye, wọ́n kéré jọjọ, àti àwọn àjèjì níbẹ̀
13 Ilia da soge enoga enogaia udigili lafiadalu. Ilia da fifilai enoga enogaia udigili lafiadalu.
wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè, láti ìjọba kan sí èkejì.
14 Be Gode da ili gaga: iba: le, eno fi da ili hame banenesi. Ili gaga: ma: ne, Gode da eno hina bagade dunu ilima amane sisane i,
Kò gba ẹnikẹ́ni láààyè láti pọ́n wọn lójú; ó fi ọba bú nítorí tiwọn:
15 “Na ilegei hawa: hamosu dunu, ilima mae se nabasima. Na balofede dunuma, mae digili ba: ma!”
“Má ṣe fọwọ́ kan ẹni àmì òróró mi; má sì ṣe wòlíì mi níbi.”
16 Hina Gode da ilia sogega ha: iasi amola ilia ha: i manu logo hedofai dagoi.
Ó pe ìyàn sórí ilẹ̀ náà ó sì pa gbogbo ìpèsè oúnjẹ wọn run;
17 Be E da dunu ea dio amo Yousefe, (e da udigili hawa: hamomusa: bidi lai) amo ili bisima: ne asunasi.
Ó sì rán ọkùnrin kan síwájú wọn Josẹfu tí a tà gẹ́gẹ́ bí ẹrú.
18 Ea emo da sia: inega la: gi amola ea galogoa sisiga: le, ouli gisa: gisu ba: i.
Wọn fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ bọ ẹsẹ̀ rẹ̀ a gbé ọrùn rẹ̀ sínú irin,
19 E da se nabawane ouesalu amogainini ea musa: ba: la: lusu liligi da dafawane doaga: i dagoi ba: i. Hina Gode Ea sia: da ea ba: la: lusu da dafawane olelei.
títí ọ̀rọ̀ tí ó sọtẹ́lẹ̀ fi ṣẹ títí ọ̀rọ̀ Olúwa fi dá a láre.
20 Amalalu, Idibidi hina bagade (e da fifi asi gala bagohame ouligisu) ea se iasu diasu logo doasima: ne sia: i.
Ọba ránṣẹ́ lọ tú u sílẹ̀ àwọn aláṣẹ ènìyàn tú u sílẹ̀
21 E da Yousefe amo Idibidi gamane ouligima: ne sia: i. E da Idibidi soge huluane, ea fawane ouligima: ne sia: i. Yousefe da eagene dunu amola hina bagade
Ó fi jẹ olúwa lórí ilẹ̀ rẹ̀, aláṣẹ lórí ohun gbogbo tí ó ní,
22 Hina bagade ea sia: beba: le, Yousefe da eagene dunu amola hina bagade ea fada: i sia: su dunu huluanema ouligi galu.
gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, kí ó máa ṣe àkóso àwọn ọmọ-aládé kí ó sì kọ́ àwọn àgbàgbà rẹ̀ ní ọgbọ́n.
23 Amalalu, Ya: igobe da Idibidi sogega asili, ha: ini fi.
Israẹli wá sí Ejibiti; Jakọbu sì ṣe àtìpó ní ilé Hamu.
24 Hina Gode da Ea fi dunuma, mano bagohame i. E da ilima ha lai dunu baligima: ne, gasa bagade Ea fi dunuma i.
Olúwa, sì mú àwọn ọmọ rẹ̀ bí sí i ó sì mú wọn lágbára jù àwọn ọ̀tá wọn lọ
25 Hina Gode da hamobeba: le, Idibidi dunu da Gode Ea fi dunuma bagade higasu. Idibidi dunu da Isala: ili dunuma bagadewane ogogosu.
Ó yí wọn lọ́kàn padà láti kórìíra àwọn ènìyàn láti ṣe àrékérekè sí àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.
26 Amalalu, Gode da Ea ilegei hawa: hamosu dunu Mousese amola Elane ela asunasi.
Ó rán Mose ìránṣẹ́ rẹ̀, àti Aaroni tí ó ti yàn.
27 Ela da Gode Ea gasa bagade hou amola musa: hame ba: su hou amo Idibidi soge ganodini hamoi.
Wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn ó ṣe iṣẹ́ ìyanu ní Hamu.
28 Gode da Idibidi sogega gasi iasi. Be Idibidi dunu da Ea hamoma: ne sia: i nabawane hame hamoi.
Ó rán òkùnkùn, o sì mú ilẹ̀ ṣú wọn kò sì sọ̀rọ̀-òdì sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
29 E da ilia hano huluane maga: me a: i asili, menabo huluane bogogia: i.
Ó sọ omi wọn di ẹ̀jẹ̀, ó pa ẹja wọn.
30 Guama da ilia soge huluane nabalesi. Hina bagade ea diasu amolawane guamaga nabalesi.
Ilẹ̀ mú ọ̀pọ̀lọ́ jáde wá, èyí tí ó lọ sí ìyẹ̀wù àwọn ọba wọn.
31 Gode da hamoma: ne sia: beba: le, gagoba: amola mimini da soge huluane ganodini bagadewane wa: le lafia: su.
Ó sọ̀rọ̀, onírúurú eṣinṣin sì dìde, ó sì hu kantíkantí ní ilẹ̀ wọn
32 E da gibu mae iawane, mugene amola ha: ha: na fawane ilia sogega iasi.
Ó sọ òjò di yìnyín, àti ọ̀wọ́-iná ní ilẹ̀ wọn;
33 Amoga E da ilia waini efe amola figi ifa amola ifa huluane gugunufinisi dagoi.
Ó lu àjàrà wọn àti igi ọ̀pọ̀tọ́ wọn ó sì dá igi orílẹ̀-èdè wọn.
34 E da hamoma: ne sia: beba: le, danuba: wa: i osea: i, idimu hamedeidafa, amo ilima asunasi.
Ó sọ̀rọ̀, eṣú sì dé, àti kòkòrò ní àìníye,
35 Ilia da ifalabo amola ha: i manu bugi amo huluane na dagoi.
wọn sì jẹ gbogbo ewé ilẹ̀ wọn, wọ́n sì jẹ èso ilẹ̀ wọn run.
36 E da Idibidi sosogo fi magobo dunu mano huluane fane lelegei.
Nígbà náà, ó kọlu gbogbo àwọn ilẹ̀ wọn, ààyò gbogbo ipá wọn.
37 Amalalu, E da Isala: ili dunu gadili oule asi. Ilia da silifa amola gouli gisawene gadili asi. Ilia huluane da dagumui amola gasa bagade ba: i.
Ó mú Israẹli jáde ti òun ti fàdákà àti wúrà, nínú ẹ̀yà rẹ̀ kò sí aláìlera kan.
38 Idibidi dunu da iliba: le beda: i, amola ili ahoabeba: le hahawane ba: i.
Inú Ejibiti dùn nígbà tí wọn ń lọ, nítorí ẹ̀rù àwọn Israẹli ń bá wọ́n.
39 Gode da Ea fi dunuma mu mobiga dedeboi. Amola gasia hadigima: ne lalu iasi.
Ó ta àwọsánmọ̀ fún ìbòrí, àti iná láti fún wọn ní ìmọ́lẹ̀ lálẹ́.
40 Ilia Ema edegeiba: le, e da ilima aiyei (quail) sio i. E da Hebeneganini, ili sadima: ne, ha: i manu i.
Wọn béèrè, ó sì mú ẹyẹ àparò wá, ó sì fi oúnjẹ ọ̀run tẹ́ wọn lọ́rùn.
41 E da igi da: iya fabeba: le, hano fudagala: le, musa: le sa: ili, hano bagadewane hafoga: i sogega hano yogo asi.
Ó sì la àpáta, ó sì mú omi jáde; gẹ́gẹ́ bí odò tí ń sàn níbi gbígbẹ.
42 E da musa: Ea hawa: hamosu dunu A: ibalaha: mema hadigi ilegele sia: su, amo bu dawa: i.
Nítorí ó rántí ìlérí mímọ́ rẹ̀ àti Abrahamu ìránṣẹ́ rẹ̀.
43 Amaiba: le, e da Ea ilegei fi dunu gadili oule asi. Amola ilia da hahawaneba: le, nodone gesami hea: i amola wele sia: i.
Ó sì fi ayọ̀ mú àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde pẹ̀lú ayọ̀ ní ó yan àyànfẹ́ rẹ̀
Ó fún wọn ní ilẹ̀ ìní náà, wọ́n sì jogún iṣẹ́ àwọn ènìyàn náà,
45 Ea fi dunu da Ea sema amo noga: le nabawane hamoma: ne, amola Ea hamoma: ne sia: i amo huluane noga: le fa: no bobogema: ne, E da eno dunu fi ilia soge samogene, Ea fi dunuma i. Amola Ea fi dunu da eno dunu ilia bugili nasu soge gesoama: ne, E da logo doasi. Hina Godema nodoma!
kí wọn kí ó lè máa pa àṣẹ rẹ̀ mọ́ kí wọn kí ó lè kíyèsi òfin rẹ̀. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.