< Idisu 23 >

1 Ba: ila: me da Ba: ila: gema amane sia: i, “Na hou fidima: ne, goeguda: oloda agoane gaguma. Amola bulamagau gawali fesuale amola sibi gawali fesuale agoane, goeguda: gaguli misa!”
Balaamu wí fún Balaki pé, “Kọ́ pẹpẹ méje fún mi níbí, kí o sì mú akọ màlúù méje àti àgbò méje wá fún mi.”
2 Ba: ila: ge da ea sia: i defele hamoi. Ba: ila: ge amola Ba: ila: me ela da bulamagau gawali amola sibi gawali amo oloda afae afae amoga gobele sali.
Balaki ṣe bí Balaamu ti sọ, àwọn méjèèjì fi akọ màlúù kọ̀ọ̀kan àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
3 Amalalu, Ba: ila: me da Ba: ila: gema amane sia: i, “Goeguda: dia gobei iasu gadenene leloma. Na da asili, Hina Gode da nama gousa: ma: bela: le, amo na da hogomu. Ea nama sia: mu liligi huluane na da dima olelemu.” Amaiba: le, e da hisu agoloba: le heda: le, agolo da: iya gado lelu,
Nígbà náà Balaamu sọ fún Balaki pé, “Dúró ti ẹbọ sísun rẹ kí èmi sì lọ sí ẹ̀gbẹ́ kan. Bóyá Olúwa yóò farahàn mí. Ohunkóhun tí ó bá fihàn mí, èmi yóò wí fún ọ.” Nígbà náà ó sì lọ sí ibi gíga.
4 Gode da ema misi. Ba: ila: me da Godema amane sia: i, “Na da oloda fesuale gaguli, amo afae afae da: iya bulamagau gawali amola sibi gawali amo gobele sali.”
Ọlọ́run sì pàdé rẹ̀, Balaamu sì sọ pé, “Mo tí ṣe pẹpẹ méje, lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan mo ti fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ.”
5 Hina Gode da Ba: ila: mema ea sia: mu liligi olelelalu, Ba: ila: gema bu sia: musa: asunasi.
Olúwa sì fi ọ̀rọ̀ sí ẹnu Balaamu ó wí pé, “Padà sí ọ̀dọ̀ Balaki kí o sì jẹ́ iṣẹ́ yìí fún un.”
6 Amaiba: le, e da buhagili, Ba: ila: ge amola Moua: be ouligisu dunu huluane ea gobei iasu gadenene lelebe ba: i.
Ó sì padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ ó sì ba tí ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀, pẹ̀lú gbogbo àwọn ìjòyè Moabu.
7 Ba: ila: me da ea ba: la: lusu amoga amane sia: i, “Ba: ila: ge, Moua: be hina da na goeguda: oule misi. Na da eso mabe goumi soge, Silia soge amoga misi. ‘Na fidima: ne sia: musa: misa’ e sia: i. ‘Isala: ili fi dunu ilima gagabusu aligima: ne ilegema!’
Nígbà náà ni Balaamu sọ ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ jáde wí pé, “Balaki mú mi láti Aramu wá, ọba Moabu láti òkè ìlà-oòrùn wá Ó wí pé, ‘Wá fi Jakọbu bú fún mi; wá, kí o sì jẹ́rìí sí Israẹli.’
8 Be na da habodane Gode Ea gagabui hame ilegei dunu ilima gagabusu aligima: ne ilegema: bela: ? Na da habodane amo dunu fi wadela: lesima: ne sia: ma: bela: ? Bai Gode da amo dunu fi wadela: lesima: ne hame sia: i.
Báwo ní èmi ó ṣe fi bú àwọn tí Ọlọ́run kò fi bú? Báwo ni èmi ó ṣe bá wọn wí àwọn tí Olúwa kò bá wí?
9 Na da gado heda: le, gele da: iya amogai aligili, amo fi ba: sa. Na da agolo da: iya gadonini ili ba: lala. Ilia da fi amo da hisu esala. Ilia dawa: ! Hina Gode da ilima hahawane dogolegelema: ne hou, eno fifi asi gala ilima hahawanedogolegele hou baligisa, amo ilima i dagoi.
Láti ṣóńṣó ibi gíga orí àpáta ni mo ti rí wọn, láti orí ibi gíga ni mo ti ń wò wọ́n. Mo rí àwọn ènìyàn tí ń gbé lọ́tọ̀ wọn kò sì ka ará wọn kún ara àwọn orílẹ̀-èdè.
10 Isala: ili fi iligaga fi da osobo su agoane, bagohameba: le, ilia dunu idimu da hamedei. Na da bogosea, na da Gode Ea fi dunu afae defele bogomu da defea. Na da bogosea, na da olofole, dunu moloidafa bogomu da defea gala.”
Ta ni ó lè ka eruku Jakọbu tàbí ka ìdámẹ́rin Israẹli? Jẹ́ kí èmi kú ikú olódodo, kí ìgbẹ̀yìn mi kí ó dà bí tirẹ̀!”
11 Amalalu, Ba: ila: ge da Ba: ila: mema amane sia: i, “Di da nama adi hamobela: ? Na da di na ha lai dunu ilima gagabui aligima: ne ilegemusa: goeguda: oule misi. Be di da amo mae hamone, ilima hahawane dogolegele hou fawane aligima: ne ilegei dagoi.”
Balaki sọ fún Balaamu pé, “Kí lo ṣe fún mi? Mo gbé ọ wá láti fi àwọn ọ̀tá mi bú, ṣùgbọ́n o kò ṣe nǹkan kan, ṣùgbọ́n o bùkún wọn!”
12 Ba: ila: me da bu adole i, “Na da Hina Gode Ea nama sia: i liligi amo fawane adomusa: dawa: !”
Ó sì dáhùn wí pé, “Ṣé kí n má sọ nǹkan tí Olúwa fi sí mi lẹ́nu?”
13 Amalalu, Ba: ila: ge da Ba: ila: mema amane sia: i, “Eno sogebi amoga nama sigi misa. Amogawi, di da Isala: ili dunu ba: lalu, na fidima: ne, ilima gagabusu aligima: ne ilegema.”
Nígbà náà Balaki sọ fún un pé, “Wá pẹ̀lú mi sí ibòmíràn tí o ti lè rí wọn; wà á rí díẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo wọn. Láti ibẹ̀, wá fi wọ́n bú fún mi.”
14 E da Ba: ila: me amo Soufime sogebi Bisiga Goumi gadodili diala amoga oule asi. Amola amogawi e da oloda fesuale gaguli amola amo afae afae amoga bulamagau gawali amola sibi gawali gobele sali.
Ó sì lọ sí pápá Sofimu ní orí òkè Pisga, ó sì kọ́ pẹpẹ méje síbẹ̀ ó sì fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
15 Ba: ila: me da Ba: ila: gema amane sia: i, “Goeguda: dia gobei iasu gadenene leloma. Amola na da ga (south) asili, Gode gousa: mu.”
Balaamu ṣo fún Balaki pé, “Dúró níbí ti ẹbọ sísun rẹ nígbà tí mo bá lọ pàdé rẹ̀ níbẹ̀.”
16 Hina Gode da Ba: ila: mema misini, ea sia: mu liligi ema olelei. E da amo Ba: ila: gema olelema: ne, bu asunasi.
Olúwa pàdé Balaamu ó sì fi ọ̀rọ̀ sí ní ẹnu wí pé, “Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Balaki kí o sì jíṣẹ́ fún un.”
17 Amaiba: le, Ba: ila: me da buhagili, Ba: ila: ge amola Moua: be ouligisu dunu, ea gobei iasu gadenene lelebe ba: i. Ba: ila: ge da Hina Gode Ea sia: ne iasu amo ema adole ba: i.
Nígbà náà ó lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ ó sì bá à tí ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìjòyè Moabu. Balaki sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni Olúwa wí?”
18 Amalalu, Ba: ila: me da ea ba: la: lusu amane sia: i, “Ba: ila: ge, Sibo ea mano! Misa! Na sia: nabima!
Nígbà náà ó bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ sísọ, “Dìde, Balaki; kí o sì gbọ́ mi ọmọ Sippori.
19 Osobo bagade dunu da ogogosu dawa: Be Gode da ogogosu hamedafa dawa. Osobo bagade dunu da ilia asigi dawa: su hedolo afadenesa. Be Gode da agoai hame dawa: Gode da Ea ilegei sia: amo huluane hamosa. E da sia: sea, Ea sia: i liligi da hamoi dagoi ba: sa.
Ọlọ́run kì í ṣe ènìyàn, tí yóò fi purọ́, tàbí ọmọ ènìyàn, tí ó lè yí ọkàn rẹ̀ padà. Ǹjẹ́ ó sọ̀rọ̀ kí ó má ṣe é? Ǹjẹ́ ó ti ṣèlérí kí ó má mu un ṣẹ?
20 E da nama hahawane dogolegele sia: fawane sia: ma: ne sia: i. Amo Gode da hahawane dogolegele aligima: ne sia: sea, na da amo sia: bu afadenemu hame dawa:
Èmi gba àṣẹ láti bùkún; Ó sì ti bùkún, èmi kò sì lè yípadà.
21 Na da agoane ba: sa. Isala: ili fi ilia hobea misunu hou amo ganodini da se nabasu amola bidi hamosu hame ba: mu. Bai Hina Gode, ilia Gode, da ili esala. E da ilia Hina Bagadedafa, ilia da amane wele sisia: sa.
“Kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kankan nínú Jakọbu, kò sì rí búburú kankan nínú Israẹli. Olúwa Ọlọ́run wọn sì wà pẹ̀lú wọn. Ìhó ọba sì wà pẹ̀lú wọn.
22 Gode da ili Idibidi sogega fisili masa: ne, goeguda: oule misi. E da sigua bulamagau defele, ili fidima: ne gegenana.
Ọlọ́run mú wọn jáde láti Ejibiti wá, wọ́n ní agbára màlúù ẹhànnà.
23 Isala: ili dunu hasalimusa: da wamuni dawa: su o yagono hou hamomu da hamedei. Wali dunu huluane da Isala: ili ea hou ba: sea amane sia: mu, ‘Ba: ma! Gode Ea hamoi ba: ma!’
Kò ní àfọ̀ṣẹ sí Jakọbu, tàbí àfọ̀ṣẹ sí àwọn Israẹli. Nísinsin yìí a ó sọ nípa ti Jakọbu àti Israẹli, ‘Wo ohun tí Ọlọ́run ti ṣe!’
24 Isala: ili fi da gasa bagade laione wa: me agoane. E da mae helefili, hu dodosa: sa amola naha amola medole legei liligi ea maga: me naha. Mai dagoiba: le fawane helefisa.”
Àwọn ènìyàn náà yóò dìde bí abo kìnnìún; wọ́n yóò sì gbé ara wọn sókè bí i kìnnìún òun kì yóò sì dùbúlẹ̀ títí yóò fi jẹ ohun ọdẹ títí yóò sì fi mu nínú ẹ̀jẹ̀ ohun pípa.”
25 Amalalu, Ba: ila: ge da Ba: ila: mema amane sia: i, “Di da Isala: ili dunu ilima gagabusu aligima: ne ilegemusa: higasa. Defea! Be ilima hahawane dogolegele hou maedafa aligima: ne ilegema!”
Nígbà náà ni Balaki wí fún Balaamu pé, “O kò kúkú fi wọ́n bú, bẹ́ẹ̀ ni o kò súre fún wọn rárá!”
26 Be Ba: ila: me da amane bu adole i, “Na da dima sia: i dagoi! Na da Hina Gode nama sia: i liligi fawane hamomusa: defele gala!”
Balaamu dáhùn ó sì wí fún Balaki pé, “Ǹjẹ́ èmi kò ha ti wí fún ọ pé, gbogbo èyí tí Olúwa bá sọ, òun ni èmi yóò ṣe?”
27 Ba: ila: ge da amane sia: i, “Ania da eno sogebi amoga ahoa: di! Amabela: ? Gode da di amoga Isala: ili dunu gagabusu aligima: ne ilegemusa: , amogawi dia logo doasima: bela: ?”
Nígbà náà Balaki sọ fún Balaamu pé, “Wá jẹ́ kí èmi kí ó mú ọ lọ sí ibòmíràn bóyá yóò tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn kí ó fi wọ́n bú láti ibẹ̀ lọ.”
28 Amaiba: le, e da Ba: ila: me amo oule asili, Bio Goumi amoba: le heda: i. Amogawi, wadela: i hafoga: i soge da elea midadi gududi ba: i.
Balaki gbé Balaamu wá sí orí òkè Peori, tí ó kọjú sí aginjù.
29 Ba: ila: me da ema amane sia: i, “Goeguda: oloda fesuale agoane gaguli, nama bulamagau gawali fesuale gala amola sibi gawali fesuale gala amo gaguli misa.”
Balaamu sì wí fún Balaki pé, “Mọ pẹpẹ méje fún mi níbí kí o sì pèsè akọ màlúù àti àgbò fún mi.”
30 Ba: ila: ge da ea sia: i defele hamoi. E da oloda afae afae amoga bulamagau gawali afae amola sibi gawali afae gobele sali.
Balaki sì ṣe bí Balaamu ti sọ fún un, ó sì gbé akọ màlúù kan àti àgbò lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.

< Idisu 23 >