< Idisu 10 >

1 Hina Gode da Mousesema amane sia: i,
Olúwa sọ fún Mose pé,
2 “Silifa dabagala: le dalabede aduna hahamoma. Amoga, Isala: ili dunu gilisima: ne amola fisisu muguluma: ne eso olelema.
“Ṣe fèrè fàdákà méjì pẹ̀lú fàdákà lílù, kí o máa lò ó láti máa fi pe ìjọ ènìyàn àti láti máa fi darí ìrìnàjò lọ sí ibùdó yín.
3 Dalabede aduna dusia, ela ga: da badilia lalaba ahoasea, amo da Isala: ili dunu huluanedafa da dima, Na Abula Diasu logo holeiga gilisima: ne, dawa: digima: ne dusa.
Nígbà tí o bá fọn méjèèjì gbogbo ìjọ ènìyàn yóò pé síwájú rẹ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
4 Be dalabede afae fawane dusia, fi ouligisu dunu fawane da gilisima: ne galebeya dawa: ma.
Bí ó bá jẹ́ ọ̀kan ni o fọn, nígbà náà ni àwọn olórí ẹ̀yà Israẹli yóò péjọ síwájú rẹ.
5 Dalabede aduna da dunumugini dusia, fi amo da fisisu eso mabe la: ididili esala da gadili masa: ne sia: ma.
Nígbà tí o bá fun ìpè ìdágìrì, àwọn ẹ̀yà tó pa ibùdó sí ìhà ìlà-oòrùn ni yóò gbéra.
6 Be dalabede da dunumugini aduna agoane dusia, fi amo da ga (south) la: idili esala da gadili masa: ne sia: ma. Amaiba: le, dilia da dalabede da dunumuni agoane dusu nabasea, fisisu mugulumusa: momagema: ma.
Nígbà tí o bá fun ìpè ìdágìrì kejì, ibùdó tó wà ní ìhà gúúsù ni yóò gbéra. Ìpè ìdágìrì yìí ni yóò jẹ́ àmì fún gbígbéra.
7 Be dilia Isala: ili dunu huluane gilisimusa: dawa: sea, sedagiliwane dalabede fulaboma: ma.
Nígbà tí o bá fẹ́ pe ìjọ ènìyàn jọ, fun fèrè nìkan, má ṣe fun ti ìdágìrì pẹ̀lú rẹ̀.
8 Gobele salasu dunu (Elane ea mano) da dalabede fulaboma: ne sia: ma. Eso huluane, mae fisili, amo hamoma: ne sia: i noga: le ouligima.
“Àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà ni kí ó máa fun fèrè. Èyí yóò jẹ́ ìlànà láéláé fún yín àti fún ìran tó ń bọ̀.
9 Dilia soge ganodini, gegesu ba: beba: le, ha lai dunu da dilima doagala: sea, dilia gegemusa: gini, dalabede duma. Na, dilia Hina Gode, da dili fidimu amola dilia ha lai dunu dili mae hasalima: ne gaga: mu.
Nígbà tí ẹ bá lọ jagun pẹ̀lú àwọn ọ̀tá tó ń ni yín lára ní ilẹ̀ yín, ẹ fun ìpè ìdágìrì pẹ̀lú fèrè. A ó sì rántí yín níwájú Olúwa, Ọlọ́run yín yóò sì gbà yín lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín.
10 Amola dilia hahawane eso amoga dilia Oubi Gaheabolo Lolo Nasu amola Hina Godema dawa: ma: ne Lolo Nasu eno amoga, dilia Wadela: i Hou Dabe Ima: ne Iasu amola Hahawane Gilisili Olofole Iasu hahamosea, dalabede fulaboma. Amasea, Na da dili fidimu. Bai Na da dilia Hina Gode.”
Bẹ́ẹ̀ náà ni ní ọjọ́ ayọ̀ yín, ní gbogbo àjọ̀dún tí a yàn àti ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yín, ni kí ẹ máa fun fèrè lórí ẹbọ sísun àti ọrẹ àlàáfíà yín, wọn yóò sì jẹ́ ìrántí fún yín níwájú Ọlọ́run. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”
11 Eso 20 amola oubi ageyadu amola ode ageyadu ganodini, Hina Gode da mumobi ganumu Ea Abula Diasu gadodili dialu amo gaguia gadole asi.
Ní ogúnjọ́ oṣù kejì, ní ọdún kejì ni ìkùùkuu kúrò lórí tabanaku ẹ̀rí.
12 Isala: ili fi dunu da Sainai hafoga: i soge amo fisili asi. Mumobi ganumu da ahoanu, Ba: ila: ne hafoga: i sogega oulelu.
Àwọn ọmọ Israẹli sì gbéra kúrò ní aginjù Sinai wọ́n sì rin ìrìnàjò wọn káàkiri títí tí ìkùùkuu fi dúró sí aginjù Parani.
13 Amaiba: le, ilia da Hina Gode Ea Mousesema hamoma: ne sia: i defele, degabo agoane asi.
Wọ́n gbéra nígbà àkọ́kọ́ yìí nípa àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose.
14 Amola eso huluane ahoabeba: le, ilia da hou ilegei defele ahoasu. Dunu fi amo da Yuda fi ilima gilisi da eso gosagisu fa: no, fi eno fi eno ahoasu. Na: iasione (Aminida: be ea egefe) da amo gilisisu ouligisu.
Àwọn ìpín ti ibùdó Juda ló kọ́kọ́ gbéra tẹ̀lé wọn lábẹ́ ogun wọn Nahiṣoni ọmọ Amminadabu ni ọ̀gágun wọn.
15 Nida: niele (Sua ea egefe) da Isaga fi amo ouligisu.
Netaneli ọmọ Suari ni ọ̀gágun ti ẹ̀yà Isakari;
16 Ilia: be (Hilone ea mano) da Sebiulane fi amo ouligisu.
Eliabu ọmọ Heloni ni ọ̀gágun ni ìpín ti ẹ̀yà Sebuluni.
17 Amalalu, ilia da Gode Ea Abula Diasu mugululi, Gesione amola Milalai fi dunu da amo gaguli ahoasu.
Nígbà náà ni wọ́n sọ tabanaku kalẹ̀ àwọn ọmọ Gerṣoni àti Merari tó gbé àgọ́ sì gbéra.
18 Amalalu, fi amo da Liubene fi ilima fa: no bobogesu, ilia da gilisisu eno eno agoane ahoasu. Elaise (Siediua egefe) da ili ouligisu.
Àwọn ìpín ti ibùdó ti Reubeni ló gbéra tẹ̀lé wọn, lábẹ́ ọ̀págun wọn. Elisuri ọmọ Ṣedeuri ni ọ̀gágun wọn.
19 Sieliumiele (Siulisia: dai egefe) da Simione fi amo ouligisu.
Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai ni ọ̀gágun ti ẹ̀yà Simeoni.
20 Ilaiasa: fe (Diuele egefe) da Ga: de fi ouligisu.
Eliasafu ọmọ Deueli ni ọ̀gágun ìpín ti ẹ̀yà Gadi.
21 Amalalu, Lifai fi amo Gouha: de da sema liligi gaguli ahoasu. Ilia da asili, fisisu sogebi eno amoga doaga: loba, Gode Ea Abula Diasu bu hiougili dagoi ba: su.
Nígbà náà ni àwọn ọmọ Kohati tí ń ru ohun mímọ́ náà gbéra. Àwọn ti àkọ́kọ́ yóò sì ti gbé tabanaku dúró kí wọn tó dé.
22 Lifai fi da asi dagoi ba: loba, fi gilisisu amo da Ifala: ime fi da ouligisu da logoga ahoanebe ba: su. Ilia ouligisu dunu da Ilisiama (Amihade egefe) ba: i.
Àwọn ìpín tó wà ní ibùdó Efraimu ló tún kàn lábẹ́ ọ̀págun wọn. Eliṣama ọmọ Ammihudu ni ọ̀gágun wọn.
23 Amo gilisisu ganodini, Gama: iliele (Bedase egefe) da Ma: na: se fi amo ouligisu.
Gamalieli ọmọ Pedasuri ni ọ̀gágun ìpín ti ẹ̀yà Manase.
24 Amola Abaida: ne (Gidioni egefe) da Bediamini fi amo ouligisu.
Abidani ọmọ Gideoni ni ọ̀gágun ìpín ti ẹ̀yà Benjamini.
25 Fa: nodafa, fi amo da Da: ne fi gilisili fi da ilia eso gosa: gisu fa: no bobogele ahoasu. Ilia da fi huluane ilia fa: no sosodo ouligisu dunu agoane ba: i. Amo gilisisu ilia ouligisu dunu da Ahaisa (Amisia: dai egefe).
Lákòótan, àwọn ọmọ-ogun tó ń mójútó ẹ̀yìn ló tún kàn, àwọn ni ìpín ti ibùdó Dani lábẹ́ ọ̀págun wọn. Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai ni ọ̀gágun wọn.
26 Ba: idiele (Ogela: ne egefe) da A: sie fi amo ouligisu.
Pagieli ọmọ Okanri ni ìpín ti ẹ̀yà Aṣeri,
27 Amola Ahaila (Ina: ne egefe) da Na: fadalai fi amo ouligisu.
Ahira ọmọ Enani ni ọ̀gágun ti ẹ̀yà Naftali.
28 Isala: ili dunu da ilia fisisu yolesili, logoga ahoanoba, agoane fi eno fi eno agoane mogodigili ahoasu.
Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe tò jáde gẹ́gẹ́ bí ogun nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wọn.
29 Mousese da ea bae amo Houba: be (Midiane dunu Yedelou egefe) ema amane sia: i, “Ninia da soge amo Hina Gode da ninima imunusa: ilegei, amoga doaga: musa: masunu. E da Isala: ili dunu hahawane bagade gaguiwane esalumusa: ilegele sia: i. Amaiba: le, di ani masunu. Ninia da di amola gilisili hahawane bagade gaguiwane hou ba: mu.”
Mose sì sọ fún Hobabu ọmọ Reueli ará Midiani tí í ṣe àna rẹ̀ pé, “A ń gbéra láti lọ sí ibi tí Olúwa sọ pé, ‘Èmi ó fi fún un yín.’ Bá wa lọ, àwa ó ṣe ọ́ dáradára nítorí pé Olúwa ti ṣèlérí ohun rere fún Israẹli.”
30 Be Houba: be da bu adole i, “Hame mabu! Na da ni sogega buhagimu.”
Ó sì dáhùn pé, “Rárá, èmi kò ní bá yín lọ, mò ń padà lọ sí ilẹ̀ mi àti sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi.”
31 Be Mousese da ema ha: giwane edegei, “Dia nini mae yolesima! Di da hafoga: i soge ganodini nini hahawane fima: ne, sogebi huluane dawa: Dia ninima logo olelema: ne misa. Hina Gode da ninima hahawane bagade imunusa: sia: i.
Mose sì sọ pé, “Jọ̀wọ́ ma fi wá sílẹ̀, ìwọ mọ ibi tí a lè pa ibùdó sí nínú aginjù, ìwọ yóò sì jẹ́ ojú fún wa.
32 Di amola ninia gilisili ahoasea, ninia da gilisili Gode Ea hahawane dogolegele iabe hou amo ba: mu.”
Bí o bá bá wa lọ, a ó sì pín fún ọ nínú ohun rere yówù tí Olúwa bá fún wa.”
33 Isala: ili dunu da hadigi goumi Sainai amo fisili asili, eso udiana agoane logoga asi. Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili ilima fisisu sogebi hogomusa: , bisili ahoanebe ba: su.
Wọ́n sì gbéra láti orí òkè Olúwa ní ìrìn ọjọ́ mẹ́ta. Àpótí ẹ̀rí Olúwa ń lọ níwájú wọn fún gbogbo ọjọ́ mẹ́ta yìí láti wá ibi ìsinmi fún wọn.
34 Hou da eso huluane agoane ba: i. Ilia da fisisu fisili ahoabeba: le, Hina Gode Ea mu mobi ganumu da esoga ili gadodili lelebe ba: i.
Ìkùùkuu Olúwa wà lórí wọn lọ́sàn nígbà tí wọ́n gbéra kúrò ní ibùdó.
35 Eso huluane ilia da Sema Gagili amo gaguli ahoabeba: le, Mousese da amane sia: su, ‘Hina Gode! Di wa: legadoma! Dia ha lai dunu amo afagogolisima! Dima higa: i dunu hobeama: ne, sefasima!”
Nígbàkígbà tí àpótí ẹ̀rí bá gbéra Mose yóò sì wí pé, “Dìde, Olúwa! Kí a tú àwọn ọ̀tá rẹ ká, kí àwọn tí ó kórìíra rẹ sì sálọ níwájú rẹ.”
36 Amola Sema Gagili da oulelea, e da amane sia: su, “Hina Gode! Dia Isala: ili dunu sosogo fi osea: i, ilima buhagima!”
Nígbàkígbà tí àpótí ẹ̀rí bá sinmi yóò wí pé, “Padà, Olúwa, sọ́dọ̀ àwọn àìmoye ẹgbẹẹgbẹ̀rún Israẹli.”

< Idisu 10 >