< Maga 3 >

1 Yesu da sinagoge diasuga bu doaga: sea, E da dunu amo ea lobo gadoi dialu ba: i.
Nígbà tí Jesu wá sí Sinagọgu. Sì kíyèsi i ọkùnrin kan wà níbẹ̀, tí ọwọ́ rẹ̀ kan rọ.
2 Fa: lisi dunu esalu da Yesuma ougiwane diwaneya udidimu hanaiba: le, Ea hou nani sosodoi. E da Helefisu (Sa: bade) esoga hawa: hamoma: bela: ? amo ilia asigi dawa: su ganodini dawa: i galu.
Àwọn kan nínú wọn sì ń wa ọ̀nà láti fi ẹ̀sùn kan Jesu. Nítorí náà, wọ́n ń ṣọ́ Ọ bí yóò mú un láradá ní ọjọ́ ìsinmi.
3 Yesu da lobo gadoi dunuma amane sia: i, “Di da dunu huluane ba: ma: ne diasu dogoa leloma!”
Jesu wí fún ọkùnrin tí ọwọ́ rẹ̀ rọ náà pé, “Dìde dúró ní iwájú ìjọ ènìyàn.”
4 Yesu da Fa: lisi dunuma amane sia: i, “Sa: bade eso ganodini hou ida: iwane hamomu da defeala: ? O amo eso ganodini wadela: i hou hamomu da defeala: ? Sa: bade esoga dunu uhinisimu da defeala: ? O medole legemu da defeala: ?” Be ilia da ouiya: le esalu.
Nígbà náà ni Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ǹjẹ́ ó bá òfin mu ní ọjọ́ ìsinmi bóyá láti ṣe rere, tàbí láti ṣe búburú! Láti gbà ẹ̀mí là, tàbí pa á run?” Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́ láìfèsì.
5 Ilia hame asigi hou ba: beba: le, Yesu da se nabi. E da ilima ougiliwane ba: i. E da lobo gadoi dialu dunuma amane sia: i, “Dia lobo moloma!” Amo sia: nababeba: le, e da ea lobo moloi. Amalalu, ea lobo da bu ida: iwane ba: i.
Nígbà tí ó sì wo gbogbo wọn yíká pẹ̀lú ìbínú, ọkàn rẹ̀ sì bàjẹ́ nítorí líle àyà wọn, ó sọ fún ọkùnrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ jáde.” Ó nà án jáde, ọwọ́ náà sì bọ̀ sípò padà pátápátá.
6 Fa: lisi dunu da gadili asili, ilia amola Helode ea fidisu dunu, ilia da Yesu fuga: musa: , gilisili sia: dalu.
Lójúkan náà, àwọn Farisi jáde lọ, láti bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Herodu gbìmọ̀ pọ̀, bí wọn yóò ṣe pa Jesu.
7 Amo soge yolesili, Yesu amola Ea ado ba: su dunu da Ga: lili Hano Wayabo bega: asi. Ga: lili soge dunu, Yudia soge dunu, Yelusaleme dunu, Idiumia dunu, Yodane Hano gusudili bega: fi dunu, Daia dunu amola Saidone dunu, amo bagohame ilia Yesu Ea hamobe nababeba: le, Ema doaga: i.
Jesu pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ yẹra kúrò níbẹ̀ lọ sí etí Òkun. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn láti Galili àti Judea sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
8
Nígbà tí wọ́n gbọ́ ìròyìn iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe, ọ̀pọ̀ ènìyàn sì tọ̀ ọ́ wá láti Judea, Jerusalẹmu àti Idumea, àti láti apá kejì odò Jordani àti láti ìhà Tire àti Sidoni.
9 Dunu bagohame da E osa: le heda: sa: besa: le, E da Ea ado ba: su dunu ilima ilia da dusagai momagema: ne sia: i.
Nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn, Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti ṣètò ọkọ̀ ojú omi kékeré kan sílẹ̀ fún un láti lọ, láti lé àwọn èrò sẹ́yìn.
10 Yesu da dunu bagohame uhinisiba: le, oloi dunu Yesu Ea da: i digili ba: ma: ne bagadewane eno dunu gua: ne fasili, digili ba: musa: misi.
Nítorí tí ó mú ọ̀pọ̀ ènìyàn láradá, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn aláìsàn ló bí ara wọn lù ú láti fi ọwọ́ kàn án.
11 Dunu ilia dogo ganodini Fio a: silibu aligila sa: i da Yesu ba: sea, osoboga diasa: ili amane gusa: ne welalu, “Di da Gode Egefe!”
Ìgbàkúgbà tí àwọn tí ó ni ẹ̀mí àìmọ́ bá ti fojú ri, wọ́n á wólẹ̀ níwájú rẹ̀. Wọn a sì kígbe lóhùn rara wí pé, “Ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run.”
12 Be Yesu da amo wadela: i a: silibu ilima ilia da Ea hou eno dunuma mae adoma: ne gagabole sia: i.
Ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn gidigidi, kí wọn má ṣe fi òun hàn.
13 Amalalu, Yesu da goumiba: le heda: le, Ea ilegei dunu ili Ema misa: ne sia: i.
Jesu gun orí òkè lọ, ó sì pe àwọn kan tí ó yàn láti wà pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n sì tọ̀ ọ́ wá.
14 Amalalu, E da dunu fagoyale gala amo ilegei. Ilia da Ea baligiga aligili, amola fa: no Gode sia: olelema: ne, E da ili asunasimu sia: i.
Ó yan àwọn méjìlá, kí wọn kí ó lè wà pẹ̀lú rẹ̀, àti kí ó lè rán wọn lọ láti wàásù
15 E da wadela: i a: silibu fadegale fasima: ne amo gasa hou ilima i dagoi.
àti láti lágbára láti lé àwọn ẹ̀mí Èṣù jáde.
16 E da ado ba: su dunu fagoyale ilegei. Ilia dio da Saimone (Yesu da ea dio afadenene bu Bida dio asuli)
Wọ̀nyí ni àwọn méjìlá náà tí ó yàn: Simoni (ẹni ti ó sọ àpèlé rẹ̀ ní Peteru),
17 Ya: mese amola Ya: mese ea ola/eya Yone (Sebedi ea manola). Yesu da amo dunu aduna elama “Boanegese” dio asuli (amo dio dawa: loma: ne da `gu gelebe dunu’).
Jakọbu ọmọ Sebede àti Johanu arákùnrin rẹ̀ (àwọn ẹni tí Jesu sọ àpèlé wọ́n ní Boanaji, èyí tí ó túmọ̀ sí “àwọn ọmọ àrá”).
18 Eno da A: dalu, Filibe, Badolemiu, Ma: diu, Domase, Ya: mese (A: lafiase ea mano), Da: diase, Saimone (Selode fi dunu),
Àti Anderu, Filipi, Bartolomeu, Matiu, Tomasi, Jakọbu ọmọ Alfeu, Taddeu, Simoni tí ń jẹ́ Sealoti
19 amola Yesu E hohonosu dunu Yudase Isaga: liode.
àti Judasi Iskariotu, ẹni tí ó fi í hàn níkẹyìn.
20 Amalalu, Yesu da diasu ganodini golili sa: i. Be dunu bagohame da gilisibiba: le, E amola Ea ado ba: su dunu da ha: i manu dibi hame ba: i.
Nígbà náà ni Jesu sì wọ inú ilé kan, àwọn èrò sì tún kórajọ, tó bẹ́ẹ̀ tí Òun àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kò rí ààyè láti jẹun.
21 Amo hou nababeba: le, Yesu Ea sosogo fidafa da Yesu ouligimusa: misi. Bai dunu eno ilia amane sia: i, “E da doula ahoa,” amo sia: nababeba: le, ilia misi.
Nígbà tí àwọn ẹbí rẹ̀ gbọ́ èyí, wọ́n wá láti mú un lọ ilé, nítorí tí wọn wí pé, “Orí rẹ̀ ti dàrú.”
22 Sema olelesu dunu da Yelusaleme moilai bai bagadega misini esalu. Ilia da amane sia: i, “Wadela: i a: silibu ilia hina amo Bilisibale da Yesu Ea dogo ganodini aligila sa: i. Amo wadela: i a: silibu ilia hina ea gasaga E da wadela: i a: silibu fadegale fasisa.”
Àwọn olùkọ́ni ní òfin sọ̀kalẹ̀ wá láti Jerusalẹmu, wọ́n sì wí pé, “Ó ni Beelsebulu, olórí àwọn ẹ̀mí èṣù, ni ó sì fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde!”
23 Amaiba: le, Yesu da ili misa: ne wei. E da fedege sia: ilima agoane olelei, “Sa: ida: ne hi da habodane Sa: ida: ne fadegale se fasima: bela: ?
Jesu pè wọ́n, ó sì fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀: “Báwo ni Èṣù ṣe lè lé èṣù jáde?
24 Fi afae da afafasea, gasa hameba: le dafamu.
Bí ìjọba kan bá yapa sí ara rẹ̀, ìjọba náà yóò wó lulẹ̀.
25 Moilai fi amola afafasea, gegesea, amo fi da hedolo dafamu.
Bákan náà, bí ilé kan bá sì yapa sí ara rẹ, ilé náà kí yóò le è dúró.
26 Amaiba: le, Sa: ida: ne da wa: legadosea, ea gasa afafabeba: le, hi gobele hima gegebeba: le, e da gasa hame ba: mu. Ea gasa da hamedemu.
Bí Èṣù bá sì dìde sí ara rẹ̀, tí ó sì yapa, òun kí yóò le è dúró ṣùgbọ́n òpin rẹ̀ yóò dé.
27 Dunu e da gasa bagade dunu ea liligi wamolamusa: , diasuga heda: musa: dawa: sea, e da hidadea gasa dunu ea lobo la: gili amalu ea liligi wamolasa.
Kò sí ẹni tí ó le wọ ilé ọkùnrin alágbára kan lọ, kí ó sì kó o ní ẹrù lọ, bí kò ṣe pé ó kọ́kọ́ de ọkùnrin alágbára náà ní okùn, nígbà náà ni yóò lè kó ẹrù ní ilé rẹ̀.
28 Na da dilima dafawane sia: sa! Gode da osobo bagade dunu ilia wadela: i hou amola lasogole sia: huluane gogolema: ne olofomu.
Lóòótọ́ ní mo wí fún yín, gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ni a ó dáríjì àwọn ọmọ ènìyàn, àti gbogbo ọ̀rọ̀-òdì.
29 Be nowa dunu da Gode Ea A: silibu Hadigidafa Gala amoma lasogole sia: sea, e da gogolema: ne olofosu hamedafa ba: mu. Ea wadela: i hou da mae fisili eso huluane dialalalumu.” (aiōn g165, aiōnios g166)
Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́, kì yóò rí ìdáríjì títí ayé, ṣùgbọ́n ó wà nínú ewu ẹ̀bi àìnípẹ̀kun.” (aiōn g165, aiōnios g166)
30 Ilia da Yesu Ea dogo ganodini wadela: i a: silibu da aligila sa: i dagoi, amo ilia da sia: dabeba: le, Yesu da agoane adole i.
Òun sọ eléyìí fún wọn, nítorí tí wọ́n sọ pé, “Nípa agbára ẹ̀mí àìmọ́ ló ń ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.”
31 Amalalu, Yesu Ea ame amola Ea eyalali doaga: i. Ilia da diasu gadili lelu. Ilia da Yesu ilima misa: ne sia: musa: , dunu afae Yesuma asunasi.
Nígbà náà ni àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ìyá wá, wọ́n dúró lóde, wọ́n sì ránṣẹ́ sí i, wọ́n ń pè é.
32 Dunu bagohame da Yesu gadenenewane fi. Ilia da Ema amane sia: i, “Dia ame amola Dia eyalali da gadili lela. Ilia da Di hogosa.”
Àwọn ènìyàn tí wọ́n jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀ sì wí fún un pé, “Ìyá àti àwọn arákùnrin rẹ wà lóde.”
33 Amalalu, Yesu E amane adole ba: i “Na ame amola Na eyalali da nowala: ?”
Ṣùgbọ́n ó dá wọn lóhùn wí pé, “Ta ni í ṣe ìyá mi tàbí àwọn arákùnrin mi?”
34 Amalu, E da sisiga: le sodolalu, dunu huluane bulagi ba: beba: le, amane sia: i, “Na ame amola Na eyalali da goea!
Ó sì wò gbogbo àwọn tí ó jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀ yíká, ó sì wí pé, “Àwọn wọ̀nyí ni ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi.
35 Nowa da Gode Ea hou nabawane hamosa, e da Naeya, Na aba amola Na: me esala.”
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run, òun ni arákùnrin mi àti arábìnrin mi àti ìyá mi.”

< Maga 3 >