< Malagai 2 >
1 Hina Gode Bagadedafa da gobele salasu dunu ilima amane sia: sa, “Amo hamoma: ne sia: Na da dilima sia: sa.
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ̀yin àlùfáà, òfin yìí ní fún yín.
2 Dilia hou ida: iwane hamoma. Amasea, dilia da amoga nodosudafa Nama olelemu. Be dilia Na sia: hame nabasea, Na da dilima gagabusu aligima: ne ilegemu. Wali, dunu eno da dilia hawa: hamomusa: gini, ha: i manu amola muni dilima iaha. Be dilia da Na sia: hame nabasea, Na da amo fidisu dilia mae lama: ne, gagabusu aligima: ne ilegemu. Dafawane! Na da amoga gagabusu aligima: ne ilegei dagoi. Bai dilia da Na hamoma: ne sia: i da hamedei liligi agoane dawa: sa.
Bí ẹ̀yin kò bá ni gbọ́, bí ẹ̀yin kò bá ní fi í sí àyà láti fi ọ̀wọ̀ fún orúkọ mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí; èmi yóò sì ran ègún sí orí yín, èmi yóò sì fi ìbùkún yín ré. Nítòótọ́ mó ti fi ré ná, nítorí pé, ẹ̀yin kò fi sí ọkàn yín láti bu ọlá fún mi.
3 Na da dilia mano ilima se imunu. Amola ohe dilia gobele salimusa: gaguli maha, amo ilia iga amo ganodini dilia odagi dudugimu. Amasea, dilia da enoga gaguli asili, iga gagadosu amoga gala: digi dagoi ba: mu.
“Nítorí tiyín èmí yóò ba àwọn ọmọ yín wí, èmi ó sì fi ìgbẹ́ rẹ́ yín lójú, àní àwọn ìgbẹ́ ọrẹ ọwọ́ yín wọ̀nyí, a ó sì kó yín lọ pẹ̀lú rẹ̀.
4 Be Na gousa: su amo Na da gobele salasu fi (amo da Lifai egaga fi) ilima i, amo mae fima: ne, Na da amo hamoma: ne sia: i dilima i, amo dilia da dawa: mu.
Ẹ̀yin ó sì mọ̀ pé, èmi ni ó ti rán òfin yìí sí yín, kí májẹ̀mú mi pẹ̀lú Lefi lè tẹ̀síwájú,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
5 Na gousa: su amo ganodini, Na da ilima esalusu amola hahawane hou ilima imunu ilegele sia: i. Amola amo hou, ilia da Nama nodoma: ne, Na da ilima i dagoi. Amola, amo esoga, musa: ilia da Nama nodosu amola Naba: le beda:
“Májẹ̀mú mi wà pẹ̀lú rẹ̀, májẹ̀mú ti ìyè àti àlàáfíà wà pẹ̀lú rẹ̀; mo sì fi wọn fún un, nítorí bíbẹ̀rù tí ó bẹ̀rù mi, tí ẹ̀rù orúkọ mi sì bà á.
6 Ilia da wadela: i hou fisili, moloidafa hou fawane olelesu. Ilia Nama olofoiwane esalu. Ilia moloidafa hou hamoi, be amo baligili, ilia da eno dunu wadela: i hou fisili, moloidafa hou hamoma: ne noga: le fidisu.
Òfin òtítọ́ wà ni ẹnu rẹ̀, a kò sì rí irọ́ ni ètè rẹ̀: ó ba mi rìn ní àlàáfíà àti ni ìdúró ṣinṣin, ó sì yí ọ̀pọ̀lọpọ̀ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀.
7 Gobele salasu dunu ilia hawa: hamosudafa da Gode Ea dafawaneyale dawa: su hou eno dunuma olelema: mu. Dunu amola uda da ilima asili, Na hanai dawa: su ilia dawa: mu da defea. Bai ilia da Hina Gode Bagadedafa, amo Ea sia: sia: na ahoasu dunu esala.
“Nítorí ètè àlùfáà ní òye láti máa pa ìmọ̀ mọ́, kí àwọn ènìyàn lè máa wá ìtọ́ni ni ẹnu rẹ̀: nítorí òun ni ìránṣẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
8 Be wali, dilia gobele salasu dunu da sinidigili, moloidafa logo yolesi dagoi. Dilia da giadofale olelebeba: le, dunu bagohame da giadofai dagoi. Dilia da gousa: su amo Na da dilima hamoi, amo wadela: lesi dagoi.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yapa kúrò ní ọ̀nà náà; ẹ̀yin sì ti fi ìkọ́ni yín mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kọsẹ̀; ẹ̀yin ti ba májẹ̀mú tí mo da pẹ̀lú Lefi jẹ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
9 Amaiba: le, Na da ilia dogo ganodini olelebeba: le, Isala: ili dunu da dili higamu. Bai dilia da Na hanai amo defele hame hamosa. Amola dilia da Na fi olelesea, dilia dunu huluane afae afae amoma defele hame fidisa.”
“Nítorí náà ni èmi pẹ̀lú ṣe sọ yín di ẹ̀gàn, àti ẹni àìkàsí níwájú gbogbo ènìyàn, nítorí ẹ̀yin kò tẹ̀lé ọ̀nà mi, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ń ṣe ojúsàájú nínú òfin.”
10 Ninia huluanedafa da Ada afadafa fawane esala! Gode afadafa fawane da nini huluanedafa hahamoi dagoi. Amaiba: le, ninia da abuliba: le eno dunuma dafawane hamomu sia: i liligi amo hame hamosala: ? Amola gousa: su amo Gode da ninia aowalali ilima hamoi, abuliba: le higasala: ?
Baba kan náà kí gbogbo wa ha ní? Ọlọ́run kan náà kọ́ ni ó dá wa bí? Nítorí kín ni àwa ha ṣe sọ májẹ̀mú àwọn baba wa di aláìmọ nípa híhu ìwà àrékérekè olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀?
11 Yuda fi dunu ilia Godema sia: i liligi amo ilia da wadela: lesi dagoi. Ilia da Yelusaleme moilai bai bagade ganodini amola Isala: ili soge huluane amo ganodini, wadela: i hou bagadedafa hamoi dagoi. Hina Gode da Ea Debolo amoma bagade asigisa. Be amo Debolo ilia da wadela: lesi dagoi, amola ledo agoane hamoi dagoi. Dunu da uda amo da ga fi ogogosu ‘gode’ ilima sia: ne gadosa, amo ilia da lai dagoi.
Juda ti ń hùwà àrékérekè, a sì ti hùwà ìríra ní Israẹli àti ni Jerusalẹmu: nítorí Juda tí sọ ìwà mímọ́ Olúwa di aláìmọ́, èyí tí ó fẹ́, nípa gbígbé ọmọbìnrin ọlọ́run àjèjì ni ìyàwó.
12 Hina Gode da amo dunu Isala: ili fi amoga fadegamu da defea. Amola agoai dunu ilia da Gode Ea oloda da: iya gobele salabe amoga bu hamedafa gilisima: mu.
Ní ti ẹni tí ó ṣe èyí, ẹni tí ó wù kí ó jẹ, kí Olúwa kí ó gé e kúrò nínú àgọ́ Jakọbu, bí ó tilẹ̀ mú ẹbọ ọrẹ wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
13 Dilia da eno hou amola hamobe. Dilia da Hina Gode Ea oloda da: iya gobele salimusa: liligi gaguli masea, bagade disa amola didiga: sa. Bai dilia iasu E da musa: hahawane lai, be wali E da amo higasa.
Èyí ni ohun mìíràn tí ẹ̀yin sì túnṣe. Ẹ̀yin fi omijé bo pẹpẹ Olúwa mọ́lẹ̀. Ẹ̀yin sọkún, ẹ̀yin sì ba ara jẹ́ nítorí tì Òun kò ka ọrẹ yín sí mọ́, tàbí kí ó fi inú dídùn gba nǹkan yìí lọ́wọ́ yín.
14 E da abuliba: le dilia gobele salabe amo hahawane hame ba: sala: ? dilia da agoane adole ba: sa. Bai E da dawa: i dagoi. Di da goiga udalai amoga sia: i dagoi, amo sia: di da wadela: lesi dagoi. Di da amo udama madelagi dagoi amola di da Gode ba: ma: ne amo uda hamedafa yolesimu sia: i. Be di da ogogoi dagoi.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, “Nítorí kín ní?” Nítorí Olúwa ti ṣe ẹlẹ́rìí láàrín ìwọ àti láàrín aya èwe rẹ, ẹni tí ìwọ ti ń hùwà ẹ̀tàn sí i: bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkejì rẹ ni òun jẹ́, àti aya májẹ̀mú rẹ.
15 Gode da di amola dia uda amo da: i afadafa amola a: silibu afadafa hamoi dagoi. E da abuliba: le, agoane hamobela: ? Bai alia da mano lalelegesea, ilia da Gode Ea fidafa amo ganodini esalumu. Amaiba: le, dilia uda ilima ilegele sia: sia: i liligi maedafa gua: ma.
Ọlọ́run kò ha ti ṣe wọ́n ní ọ̀kan? Ni ara àti ni ẹ̀mí tirẹ̀ ni. Èéṣe tí Ọlọ́run da yín lọ́kàn? Kí òun bá à lè wá irú-ọmọ bí ti Ọlọ́run. Nítorí náà, ẹ tọ́jú ẹ̀mí yín, ẹ má sì ṣe hùwà ẹ̀tàn sí aya èwe yín.
16 Isala: ili Hina Gode da amane sia: sa, “Na da uda fisiagasu hou amola dunu fisiagasu hou higasa. Dilia afae da dia uda amoma agoai dodona: gi hou hamosea, Na da bagadewane higasa. Dilia sia: sia: i liligi amo da dia uda di da hamedafa fisiagamu, amo sia: maedafa gua: ma.”
“Ọkùnrin tí ó bá kórìíra, tí ó sì kọ ìyàwó rẹ̀,” se ìwà ipá sí ẹni tí ó yẹ kí ó dá ààbò bò, ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun. Nítorí náà, ẹ ṣọ́ ẹ̀mí yín, kí ẹ má ṣe hùwà ẹ̀tàn.
17 Dilia da bagade sia: beba: le, Hina Gode da nabala helesa. Be dilia da amane adole ba: sa, “Ninia habodane Hina Gode helema: ne hamosala: ?” Dilia da Gode helema: ne agoane hamosa. Dilia da ogogole agoane sia: sa, “Hina Gode Bagadedafa da wadela: i hamosu dunuma hahawane bagade dawa: sa. E da ilima bagadewane asigisa.” O dilia da agoane adole ba: sa, “Dunu da Gode Ea fofada: su hou da moloidafa sia: sa. Be amo Gode da habila: ?”
Ẹ̀yin ti fi ọ̀rọ̀ yín dá Olúwa ní agara. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, “Nínú kín ni àwa fi dá a ní agara?” Nígbà tí ẹ̀yìn wí pé, “Gbogbo ẹni tí ó ṣe ibi, rere ni níwájú Olúwa, inú rẹ̀ sì dùn sí wọn,” tàbí “Níbo ni Ọlọ́run ìdájọ́ gbé wà?”