< Luge 11 >
1 Eso afaega, Yesu da sogebi afae amoga sia: ne gadolalu. Sia: ne gadoi dagoloba, Ea ado ba: su dunu afadafa da Ema amane sia: i, “Yone Ba: bodaise da ea ado ba: su dunuma sia: ne gadosu hou olelei. Di amolawane, amo hou ninima olelema!”
Bí ó ti ń gbàdúrà ní ibi kan, bí ó ti dákẹ́, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olúwa, kọ́ wa bí a ti ń gbàdúrà, bí Johanu ti kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.”
2 Amalalu, Yesu da ilima amane sia: i, “Dilia da Godema sia: ne gadosea, agoane sia: ma, ‘Ada Gode! Dia hadigi Dio amoma dunu ilia nodone dawa: mu da defea. Dia Hinadafa Hou da osobo bagadega doaga: mu da defea.
Ó sì wí fún wọn pé, “Nígbà tí ẹ̀yin bá ń gbàdúrà, ẹ máa wí pé: “‘Baba wa tí ń bẹ ní ọ̀run, kí á bọ̀wọ̀ fún orúkọ yín. Kí ìjọba yín dé, ìfẹ́ tiyín ni kí a ṣe, bí i ti ọrun, bẹ́ẹ̀ ni ní ayé.
3 Ninia wali ha: i manu defele, ha: i manu ninima ima.
Fún wa ní oúnjẹ òòjọ́ wa lójoojúmọ́.
4 Ninia wadela: i hou hamoi amo Di gogolema: ne olofoma. Bai ninia da dunu huluane amo da ninima wadela: i hou hamosea, amo gogolema: ne olofosa. Amola gasa bagade dafama: ne ado ba: su hou, amoma nini mae oule masa!’”
Kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá; nítorí àwa tìkára wa pẹ̀lú a máa dáríjì olúkúlùkù ẹni tí ó jẹ wá ní gbèsè, Má sì fà wá sínú ìdánwò, ṣùgbọ́n gbà wá lọ́wọ́ ẹni búburú ni.’”
5 Amola, Yesu da Ea fa: no bobogesu dunuma amane sia: i, “Dilia udigili fedege sia: dawa: ma. Ebeda! Dunu afadafa da gasimogoa ea sama ea diasuga doaga: sea, ema amane sia: sa, ‘Sama! Na da agi ga: gi udiana dima edegela misi.
Ó sì wí fún wọn pé, “Ta ni nínú yín tí yóò ní ọ̀rẹ́ kan, tí yóò sì tọ̀ ọ́ lọ láàrín ọ̀gànjọ́, tí yóò sì wí fún un pé, ‘Ọ̀rẹ́, yá mi ní ìṣù àkàrà mẹ́ta.
6 Bai na na: iyado eno da sofe misini, na diasuga doaga: i. Be na da ha: i manu hame.’
Nítorí ọ̀rẹ́ mi kan ti àjò dé sọ́dọ̀ mi, èmi kò sì ní nǹkan tí èmi ó gbé kalẹ̀ níwájú rẹ̀.’
7 Amasea, ea sama diasu ganodini esala da bu adole iaha amane, ‘Na golai mae didilisima! Logo da ga: si dagoi. Na amola na mano, ninia golasu ganodini hahawane diaha. Na wa: legadole imunu hihi gala.’
Tí òun ó sì gbé inú ilé dáhùn wí fún un pé, ‘Má yọ mí lẹ́nu, a ti sé ìlẹ̀kùn, àwọn ọmọ mi si ń bẹ lórí ẹní pẹ̀lú mi: èmi kò lè dìde fi fún ọ!’
8 Amo sia: nababeba: le adi hamoma: bela: ? Na dima agoane sia: sa. Goe dunu da ea sama ema asigiwane dawa: beba: le, e da hame wa: legadole imunu. Be amo dunu da mae yolele, ema gebewane adole ba: beba: le, e da wa: legadole imunu.
Mo wí fún yín, bí òun kò tilẹ̀ ti fẹ́ dìde kí ó fi fún un nítorí tí í ṣe ọ̀rẹ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n nítorí àwíìyánnu rẹ̀, yóò dìde, yóò sì fún un tó bí ó ti ń fẹ́.
9 Na da dilima sia: sa! Gebewane adole boba: lalea, dilia da lamu! Hogoi helesea, dilia da ba: mu! Mae yolele logoga lulufigisia, dilia da logo doasibi ba: mu!
“Èmí sì wí fún yín, ẹ béèrè, a ó sì fi fún un yín; ẹ wá kiri, ẹ̀yin ó sì rí; ẹ kànkùn, a ó sì ṣí i sílẹ̀ fún yín.
10 Nowa da gebewane adole boba: lalea da lamu! Nowa da hogoi helesea da ba: mu! Nowa da mae yolele, logoga lulufigisia, e da logo doasibi ba: mu!
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá béèrè, ó rí gbà; ẹni tí ó sì ń wá kiri, ó rí; àti ẹni tí ó kànkùn ni a ó ṣí i sílẹ̀ fún.
11 Osobo bagade eda da ea mano ema menabo manusa: adole ba: sea, e da medosu sania ima: bela: ? Hame mabu!
“Ta ni baba nínú yín tí ọmọ rẹ̀ yóò béèrè àkàrà lọ́dọ̀ rẹ̀, tí yóò fún un ní òkúta? Tàbí bí ó béèrè ẹja, tí yóò fún un ní ejò?
12 Ea mano da ema ha: i manusa: gagala oso adole ba: sea, eda da ema gamaloa ima: bela: ? Hame mabu!
Tàbí bí ó sì béèrè ẹ̀yin, tí yóò fún un ní àkéekèe?
13 Amaiba: le, dilia wadela: i hou hamosu dunu da dilia mano ilima liligi ida: iwane gala imunu dawa: beba: le, dilia Hebene Ada da dilima Gode Ea A: silibu Hadigidafa iasu liligi baligiliwane imunusa: dawa:”
Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin tí ó jẹ́ ènìyàn búburú bá mọ bí a ti í fi ẹ̀bùn dáradára fún àwọn ọmọ yín, mélòó mélòó ha ni Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ fún àwọn tí ó béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀!”
14 Yesu da sia: hamedei hamosu Fio liligi dunu afae ea dogo ganodini aligila sa: i, amo fadegale fasi. Amalalu, amo dunu da bu sia: baoui. Dunu huluane da bagadewane fofogadigi.
Ó sì ń lé ẹ̀mí èṣù kan jáde, tí ó sì yadi. Nígbà tí ẹ̀mí èṣù náà jáde, odi sọ̀rọ̀; ẹnu sì ya ìjọ ènìyàn.
15 Be mogili da amane sia: i, “E da Bilisibale, wadela: i a: silibu hina, amo ea gasaga Fio liligi fadegale fasisa.”
Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn wí pé, “Nípa Beelsebulu olórí àwọn ẹ̀mí èṣù ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.”
16 Eno dunu da Yesuma ado ba: ma: ne, muagadoganini gasa bagade dawa: digima: ne olelesu hamoma: ne Ema sia: i.
Àwọn ẹlòmíràn sì ń dán an wò, wọ́n ń fẹ́ àmì lọ́dọ̀ rẹ̀ láti ọ̀run wá.
17 Be Yesu da ilia asigi dawa: su dawa: beba: le, amane sia: i, “Dunu fi da afafasea, amo fi da wadela: lesi dagoi ba: mu. Diasu fi amola afafasea da dafamu.
Ṣùgbọ́n òun mọ èrò inú wọn, ó wí fún wọn pé, “Gbogbo ìjọba tí ó ya ara rẹ̀ ní ipá, ni a ń sọ di ahoro; ilé tí ó sì ya ara rẹ̀ nípá yóò wó.
18 Sa: ida: ne fi da mogili afafasea, ea fi da habodane leloma: bela: ? Na da Bilisibale ea gasa laiba: le, Na da Fio liligi fadegale fasisa, amo dilia da sia: sa.
Bí Satani ba yapa sí ara rẹ̀, ìjọba rẹ̀ yóò ha ṣe dúró? Nítorí ẹ̀yin wí pé, nípa Beelsebulu ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
19 Be Na da Bilisibale ea gasaga Fio liligi fadegale fasisia, dilima fa: no bobogesu dunu da nowa ea gasaga fadegale fasisala: ? Amaiba: le, ilia da dili ogogosu hou olelesa.
Bí ó ba ṣe pé nípa Beelsebulu ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, nípa ta ni àwọn ọmọ yín fi ń lé wọn jáde, nítorí náà àwọn ni yóò ṣe onídàájọ́ yín.
20 Be Na da Gode Ea gasa amoga Fio liligi fadegasa galea, defea, Gode Ea Hinadafa Hou da dilima doaga: i dagoi dawa: ma.
Ṣùgbọ́n bí ó bá ṣe pé nípa ìka ọwọ́ Ọlọ́run ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, ǹjẹ́ ìjọba Ọlọ́run dé bá yín tán.
21 Gasa bagade dunu da gegesu liligi gaguli, ea diasu ouligisia, ea liligi enoga wadela: mu da hamedei.
“Nígbà tí alágbára ọkùnrin tí ó ni ìhámọ́ra bá ń ṣọ́ ààfin rẹ̀, ẹrù rẹ̀ yóò wà ní àlàáfíà.
22 Be eno dunu amo ea gasa da musa: adoi dunu ea gasa baligi galea, amo da ema gegene, fane legesea, e da ea gegesu liligi amola liligi huluane gasawane samogene, gaguli asili, amo liligi momogili, ea fa: no bobogesu dunuma iaha.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹni tí ó ní agbára jù ú bá kọlù ú, tí ó sì ṣẹ́gun rẹ̀ a gba gbogbo ìhámọ́ra rẹ̀ tí ó gbẹ́kẹ̀lé lọ́wọ́ rẹ̀, a sì pín ìkógun rẹ̀.
23 Nowa dunu da Namagale hame gegesea, e da Nama ha lai dunu esala. Nowa da Na fi ilima hame gilisisia, e da Na fi wadela: musa: afagogosa.
“Ẹni tí kò bá wà pẹ̀lú mi, ó lòdì sí mi, ẹni tí kò bá sì bá mi kójọpọ̀, ó fọ́nká.
24 Wadela: i a: silibu da dunu ea dogoga fadegale fasisia, e da dunu hame esalebe sogega udigili golasu hogola ahoa. Be hame ba: beba: le, hi asigi dawa: su ganodini e da amane dawa: sa, “Na da na diasu fisi amoga buhagimu.”
“Nígbà tí ẹ̀mí àìmọ́ bá jáde kúrò lára ènìyàn, a máa rìn kiri ní ibi gbígbẹ, a máa wá ibi ìsinmi; nígbà tí kò bá sì rí, a wí pé, ‘Èmi yóò padà lọ sí ilé mi ní ibi tí mo gbé ti jáde wá.’
25 Amasea, e da buhagili, ea diasu da noga: le doga: le dagoi ba: sa.
Nígbà tí ó bá sì dé, tí ó sì rí tí a gbá a, tí a sì ṣe é ní ọ̀ṣọ́.
26 Amasea, e da bu ahoasea, a:silibu eno lobofaseleyale gala, ilia hou da ea wadela: i hou baligisa, amo lidili, misini, ilia da ganodini aligila sa: imu. Amaiba: le, amo dunu ea fa: no mabe hou da ea musa: wadela: i hou bagadewane baligimu.”
Nígbà náà ni yóò lọ, yóò sì mú ẹ̀mí méje mìíràn tí ó burú ju òun tìkára rẹ̀ lọ wá, wọn yóò wọlé, wọn yóò sì máa gbé níbẹ̀, ìgbẹ̀yìn ọkùnrin náà yóò sì burú ju ìṣáájú rẹ̀ lọ.”
27 Amo sia: Yesu E sia: i dagoiba: le, dunu gilisisu ganodini uda afadafa da ha: giwane sia: i, “Uda da ea hagomo ganodini, Di e da laiba: le amola ea dodo maga: me Dima iabeba: le, amo uda da hahawane bagade ba: sa.”
Bí ó ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí, obìnrin kan gbóhùn rẹ̀ sókè nínú ìjọ, ó sì wí fún un pé, “Ìbùkún ni fún inú tí ó bí ọ, àti ọmú tí ìwọ mu!”
28 Be Yesu E bu adole i, “Dafawane! Be nowa da Gode Ea sia: nabawane hamosea, amo dunu da baligiliwane hahawane ba: sa.”
Ṣùgbọ́n òun wí pé, nítòótọ́, kí ó kúkú wí pé, “Ìbùkún ni fún àwọn tí ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, tí wọ́n sì pa á mọ́!”
29 Yesu da dunu bagohame E guba: le aliligi, amo ilima amane sia: i, “Waha fi diala da wadela: i fi. Ilia da gasa bagade dawa: digima: ne olelesu hogosa. Be dawa: digima: ne olelesu eno Na da hame olelemu. Youna ea dawa: digima: ne olelesu fawane olelemu.
Nígbà tí ìjọ ènìyàn sì ṣùjọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí wí pé, “Ìran búburú ni èyí, wọ́n ń wá àmì; a kì yóò sì fi àmì kan fún un bí kò ṣe àmì Jona wòlíì!
30 Youna ea hou da Ninefe dunuma dawa: digima: ne olelesu hamoi. Amaiwane, Dunu Egefe da waha fi diala ilima dawa: digima: ne olelesu agoane ba: mu.
Nítorí bí Jona ti jẹ́ àmì fún àwọn ará Ninefe, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò ṣe jẹ́ àmì fún ìran yìí.
31 Gode Ea Fofada: su Eso doaga: sea, Siba gagoe (south) uda hina bagade da wa: legadole, dilima diliwaneya udidimu. Bai e da Soloumane ea bagade dawa: su sia: nabimusa: , soge badilia amodili misi. Be Soloumane ea mimogo hou baligisu dunu da waha esala.
Ọbabìnrin gúúsù yóò dìde ní ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn ìran yìí, yóò sì dá wọn lẹ́bi: nítorí tí ó ti ìhà ìpẹ̀kun ayé wá láti gbọ́ ọgbọ́n Solomoni: sì kíyèsi i, ẹni tí ó pọ̀jù Solomoni lọ ń bẹ níhìn-ín yìí.
32 Gode Ea Fofada: su Eso doaga: sea, Ninefe dunu da wa: legadole, dilima diliwaneya udidimu. Bai ilia da Youna ea sia: nababeba: le, gogosiane, Godema sinidigi. Be Dunu waha esala, Ea hou da Youna ea hou baligi dagoi.
Àwọn ará Ninefe yóò dìde ní ọjọ́ ìdájọ́ pẹ̀lú ìran yìí, wọn ó sì dá a lẹ́bi: nítorí tí wọn ronúpìwàdà nípa ìwàásù Jona; sì kíyèsi i, ẹni tí ó pọ̀jù Jona lọ ń bẹ níhìn-ín yìí.
33 Dunu da gamali wa: sea, e da hame wamolegesa, e da ofodo amoga hame dedebosa. Be e da gamali amo gamali bugisu da: iya bugibiba: le, dunu da diasu ganodini golili dasea, hadigi ba: sa.
“Kò sí ẹnìkan, nígbà tí ó bá tan fìtílà tan, tí gbé e sí ìkọ̀kọ̀, tàbí sábẹ́ òsùwọ̀n, bí kò ṣe sórí ọ̀pá fìtílà, kí àwọn tí ń wọlé ba à lè máa rí ìmọ́lẹ̀.
34 Dia si da dia da: i hodo gamali agoane. Dia si da noga: iwane galea, hadigi da dia da: i hodo nabamu. Be dia si da wadela: i galea, gasi da dia da: i hodo nabamu.
Ojú ni fìtílà ara: bí ojú rẹ bá mọ́lẹ̀ kedere, gbogbo ara rẹ a mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n bí ojú rẹ bá ṣókùnkùn, ara rẹ pẹ̀lú a kún fún òkùnkùn.
35 Amaiba: le dawa: ma! Dia hadigi da gasiwane ba: sa: besa: le, dawa: ma!
Nítorí náà kíyèsi i, kí ìmọ́lẹ̀ tí ń bẹ nínú rẹ má ṣe di òkùnkùn.
36 Dia da: i hodo da mae gasili hadigi amoga nabai galea, di da gamali ea hadigi agoane amo ganodini esalumu.”
Ǹjẹ́ bí gbogbo ara rẹ bá kún fún ìmọ́lẹ̀, tí kò ní apá kan tí ó ṣókùnkùn, gbogbo rẹ̀ ni yóò ní ìmọ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí fìtílà bá fi ìtànṣán rẹ̀ fún ọ ní ìmọ́lẹ̀.”
37 Yesu da sia: dagoloba, Fa: lisi dunu afadafa da Ema ha: i manusa: misa: ne sia: i. Amaiba: le, Yesu da ea diasu ganodini golili sa: ili, ha: i manusa: fi.
Bí ó sì ti ń wí, Farisi kan bẹ̀ ẹ́ kí ó bá òun jẹun: ó sì wọlé, ó jókòó láti jẹun.
38 Yesu da ha: i manusa: , Ea lobo hame dodofeiba: le, Fa: lisi dunu da bagadewane fofogadigi.
Nígbà tí Farisi náà sì rí i, ẹnu yà á nítorí tí kò kọ́kọ́ wẹ ọwọ́ kí ó tó jẹun.
39 Amaiba: le, Hina Yesu da ema amane sia: i, “Dilia Fa: lisi dunu da hano nasu faigelei amola ofodo dabuagado fawane dodofesa. Be ganodini dilia da gegesu amola wadela: i hou amoga nabai gala.
Olúwa sì wí fún un pé, “Ẹ̀yin Farisi a máa ń fọ òde ago àti àwopọ̀kọ́: ṣùgbọ́n, inú yín kún fún ìwà búburú àti ìrẹ́jẹ.
40 Dilia gagaoui dunu! Adi dawa: bela: ? Gode da dabuagado da: i hamoiba: le, E da ganodini hame hamoi dilia dawa: bela: ?
Ẹ̀yin aṣiwèrè, ẹni tí ó ṣe èyí tí ń bẹ lóde, òun kò ha ṣe èyí tí ń bẹ nínú pẹ̀lú?
41 Be dilia hano nasu faigelei amola ofodo amo ganodini liligi huluane hame gagui dunuma imunu da defea. Amasea, liligi huluane da ledo hamedei dilia da ba: mu.
Nípa ohun ti inú yin, ki ẹ̀yin kúkú máa ṣe ìtọrẹ àánú nínú ohun tí ẹ̀yin ní, sì kíyèsi i, ohun gbogbo ni ó di mímọ́ fún yín.
42 Dilia Fa: lisi dunu da se bagade nabimu! Dilia da ha: i manu liligi fonobahadi nabuane agoane fifili, afadafa Godema iaha. Be Gode Ea moloidafa hou amola Gode Ea asigi hou, dilia hame hamosa. Musa sia: i liligi mae fisili, fa: no sia: i liligi amola gilisili hamomu da defea galu.
“Ṣùgbọ́n ègbé ni fún yín, ẹ̀yin Farisi, nítorí tí ẹ̀yin a máa san ìdámẹ́wàá minti àti irúgbìn, àti gbogbo ewébẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kọ ìdájọ́ àti ìfẹ́ Ọlọ́run: wọ̀nyí jẹ́ ohun tí ẹ gbọdọ̀ ṣe, láìsí fi àwọn ìyókù sílẹ̀ láìṣe.
43 Dilia Fa: lisi dunu da se bagade nabimu! Dilia da sinagoge diasu ganodini, fisu ida: iwane amoga fimu hanai gala. Bidiga lama: ne diasuga ahoasea, dilia da eno dunu dilima nodone sia: mu hanai gala.
“Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin Farisi, àgàbàgebè! Nítorí tí ẹ̀yin fẹ́ ipò ọlá nínú Sinagọgu, àti ìkíni ní ọjà.
44 Dilia da se bagade nabimu. Dilia da bogoi ilia uli dogoi agoane. Amo liligi dunu ilia hame ba: beba: le, amo da: iya udigili ososa: lala.”
“Ègbé ni fún un yín, nítorí ẹ̀yin dàbí ibojì tí kò farahàn, tí àwọn ènìyàn sì ń rìn lórí rẹ̀ láìmọ̀.”
45 Sema olelesu dunu afadafa da Yesuma amane sia: i, “Olelesu! Amo sia: sia: beba: le, Di da ninima amolawane gadesa!”
Nígbà náà ni ọ̀kan nínú àwọn amòfin dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Olùkọ́, nínú èyí tí ìwọ ń wí yìí ìwọ ń gan àwa pẹ̀lú.”
46 Be Yesu E bu adole i, “Dilia sema olelesu dunu amola da se bagade nabimu! Dunu eno hamoma: ne, dilia da ga: nasidafa liligi ilima olelesa. Be amo dioi liligi gaguia gadomusa: , dilia da ili fidima: ne, lobo sogo afadafa fawane hame gaguia gadosa.
Ó sì wí pé, “Ègbé ni fún ẹ̀yin amòfin pẹ̀lú, nítorí tí ẹ̀yin di ẹrù tí ó wúwo láti rù lé ènìyàn lórí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin tìkára yín kò jẹ́ fi ìka yín kan ẹrù náà.
47 Dilia da se bagade nabimu! Dilia da balofede dunu ilia bogoi uli dogoi hahawane hamosa. Be dilia aowalalia da amo balofede dunu medole legei dagoi.
“Ègbé ni fún yín, nítorí tí ẹ̀yin kọ́ ibojì àwọn wòlíì, tí àwọn baba yín pa.
48 Amaiba: le, dilia aowalalia da balofede dunu medole legeiba: le, dilia hahawane ba: sa. Ilia da medole legei dagoi, be dilia da ilia bogoi salasu hahamosa.
Ǹjẹ́ ẹ̀yin jẹ́ ẹlẹ́rìí, ẹ sì ní inú dídùn sí iṣẹ́ àwọn baba yín, nítorí tí wọn pa wọ́n, ẹ̀yin sì kọ́ ibojì wọn.
49 Amaiba: le, Gode da Ea bagade dawa: su amoga amane sia: i, ‘Na da ba: la: lusu dunu amola adola ahoasu dunu ilima asunasimu. Mogili ilia da medole legemu, mogili ilima ilia da se bagade imunu.’
Nítorí èyí ni ọgbọ́n Ọlọ́run sì ṣe wí pé, ‘Èmi ni ó rán àwọn wòlíì àti àwọn aposteli sí wọn, wọn ó sì ṣe inúnibíni sí wọn.’
50 Amaiba: le, osobo bagade hahamosu eso amogainini wali eso, amo esoga balofede dunu huluanedafa medole legeiba: le, waha fi esala da se dabe iasu lamu. Waha fi esala ilisu da balofede dunu huluanedafa medole legei dagoi, amo defelewane Gode da ilima fofada: mu.
Kí a lè béèrè ẹ̀jẹ̀ àwọn wòlíì gbogbo, tí a ti ta sílẹ̀ láti ìgbà ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé wá, lọ́wọ́ ìran yìí;
51 A: ibele da musa: medole legei ba: i, amalu dunu bagohame medole lelegele asili, Segalaia ilia da oloda amola Hadigi Malei Sesei amo dogoa sogebi amogai medole legele, amogainini wali eso. Amo wadela: i medole legesu hou huluane waha fi esala da hamoi dagoi, amo defelewane Gode da ba: mu amola ilima se dabe imunu.
láti ẹ̀jẹ̀ Abeli wá, títí ó sì fi dé ẹ̀jẹ̀ Sekariah, tí ó ṣègbé láàrín pẹpẹ àti tẹmpili. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín ìran yìí ni yóò ru gbogbo ẹ̀bi àwọn nǹkan wọ̀nyí.
52 Dilia Sema Olelesu dunu da se bagade nabimu! Dilia da fedege agoane dawa: su diasu doasima: ne gi eno dunuma mae iawane gasawane gagusa. Dilia da amo diasu ganodini mae golili sa: ili, amola eno dunu ilia ganodini masu logo hedofasa.”
“Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin amòfin, nítorí tí ẹ̀yin ti mú kọ́kọ́rọ́ ìmọ̀ kúrò; ẹ̀yin tìkára yín kò wọlé, àwọn tí sì ń wọlé, ni ẹ̀yin ń dí lọ́wọ́.”
53 Yesu da amo sogebi fisili ahoanoba, sema olelesu dunu amola Fa: lisi dunu da Yesuma gadele ha: giwane adole ba: su.
Bí ó ti ń lọ kúrò níbẹ̀, àwọn akọ̀wé àti àwọn Farisi bẹ̀rẹ̀ sí bi í lọ́rọ̀ gidigidi, wọ́n sì ń yọ ọ́ lẹ́nu láti wí nǹkan púpọ̀.
54 Yesu dafama: ne, ilia da sia: ga bagadewane fedegele boba: su.
Wọ́n ń ṣọ́ ọ, wọ́n ń wá ọ̀nà láti rí nǹkan gbámú lẹ́nu kí wọn bá à lè fi ẹ̀sùn kàn án.