< Fofagini Disu 3 >

1 Na da Gode Ea se bidi iasu amo dawa:
Èmi ni ọkùnrin tí ó rí ìpọ́njú pẹ̀lú ọ̀pá ìbínú rẹ.
2 E da na gasidafa ganodini, amoga sefasi.
Ó ti lé mi jáde ó sì mú mi rìn nínú òkùnkùn ju ti ìmọ́lẹ̀.
3 E da mae asigiliwane, na bubulufalalu.
Nítòótọ́, ó ti yí ọwọ́ rẹ̀ padà sí mi síwájú àti síwájú sí i ní gbogbo ọjọ́.
4 E da na hu fa: gini ale sasalili amalu na gasa fifili yolesi.
Ó jẹ́ kí àwọ̀ mi àti ẹran-ara mi gbó ó sì tún ṣẹ́ egungun mi.
5 E da fedege agoane baligili se iasu diasu ganodini na ga: si.
Ó ti fi mí sí ìgbèkùn, ó sì ti yí mi ká pẹ̀lú ìkorò àti làálàá.
6 E da na seseiba: le, na da gasi ganodini bogosu gaha agoai dialu.
Ó mú mi gbé nínú òkùnkùn, bí ti àwọn tó ti kú fún ìgbà pípẹ́.
7 E da na sia: inega lala: gi dagoi. Na da fedege agoane, se iasu diasu ganodini esala. Na da hobeamu gogoleidafa.
Ó ti tì mí mọ́ ilé, nítorí náà n kò le è sálọ; ó ti fi ẹ̀wọ̀n mú mi mọ́lẹ̀.
8 Na da na fidima: ne, Godema ha: giwane disa wele sia: sa. Be E da na wele sia: su nabimu higasa.
Pàápàá nígbà tí mo ké fún ìrànlọ́wọ́, ó kọ àdúrà mi.
9 Na da emoga ahoasea, fefeloa ahoa. Na da habidili delegisia, gelega logo ga: su fawane ba: sa.
Ó fi ògiri òkúta dí ọ̀nà mi; ó sì mú ọ̀nà mi wọ́.
10 Hina Gode da nama doagala: musa: , ‘bea’ ohe agoai ouesalu. E da ‘laione’ wa: me ea hou defele, nama doagala: le, gagula dasu.
Bí i beari tí ó dùbúlẹ̀, bí i kìnnìún tí ó sá pamọ́.
11 E da na logo hamega ga sefasi. E da na da: i hodo gagadelale, dodosa: ne, na yolesi.
Ó wọ́ mi kúrò ní ọ̀nà, ó tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ ó fi mi sílẹ̀ láìsí ìrànlọ́wọ́.
12 E da Ea oulali dili, na gala: i.
Ó fa ọfà rẹ̀ yọ ó sì fi mí ṣe ohun ìtafàsí.
13 E da na Ea dadiga, na da: igadafa gano gala: i.
Ó fa ọkàn mí ya pẹ̀lú ọfà nínú àkọ̀ rẹ̀.
14 Dunu ilia da hahabe asili daeya nama oufesega: sa. Ilia da nama lalasogole oufesega: sa.
Mo di ẹni yẹ̀yẹ́ láàrín àwọn ènìyàn mi; wọn yẹ̀yẹ́ mi pẹ̀lú orin ní gbogbo ọjọ́.
15 Hina Gode da fedege agoane se nabasu fawane, ha: i manu amola hano defele nama moma: ne i.
Ó ti kún mi pẹ̀lú ewé kíkorò àti ìdààmú bí omi.
16 E da na odagi osobo da: iya bugisili, geselalu. E da na bese gelega fifilisi.
Ó ti fi òkúta kán eyín mi; ó ti tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ nínú eruku.
17 Na da da: i dioiba: le olosa, amola olofosu amola hahawane hou gogolesa.
Mo ti jìnnà sí àlàáfíà; mo ti gbàgbé ohun tí àṣeyege ń ṣe.
18 Na da fonobahadi fawane bu esalumu. Na Hina Gode da na fidima: bela: le dawa: su hame ba: sa.
Nítorí náà mo wí pé, “Ògo mi ti lọ àti ìrètí mi nínú Olúwa.”
19 Na da golasu hamedei amola se bagade nabala. Na da amo dawa: sea, amo da nama gamogai medosu hano nasu defele ba: sa.
Mo ṣe ìrántí ìpọ́njú àti ìdààmú mi, ìkorò àti ìbànújẹ́.
20 Na da na se nabasu amo mae fisili dawa: lala. Na a: silibu ganodini da: i dioi bagade nabala.
Mo ṣèrántí wọn, ọkàn mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
21 Be na da liligi afadafa dawa: sea, na dafawane hamoma: beyale dawa: su da bu nama maha.
Síbẹ̀, èyí ni mo ní ní ọkàn àti nítorí náà ní mo nírètí.
22 Amo liligi da Hina Gode Ea da nama mae fisili, asigisa. Amola E da gogolema: ne olofosu dawa:
Nítorí ìfẹ́ Olúwa tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti àánú rẹ kì í kùnà.
23 Ea asigidafa hou da hahabe nasegagi defele, amola eso ea mabe defele, hame yolesisa.
Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀; títóbi ni òdodo rẹ̀.
24 Na da liligi eno hamedafa gala. Hina Gode Hifawane da na Fidisu Dunu. Amaiba: le, na da Ema fawane dafawaneyale dawa: sa.
Mo wí fún ara mi, ìpín mi ni Olúwa; nítorí náà èmi yóò dúró dè ọ́.
25 Hina Gode da nowa dunu amo da Ea hou dafawaneyale dawa: sea, lalegagusia, amo dunuma hahawane hamosa.
Dídára ni Olúwa fún àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ̀, sí àwọn tí ó ń wá a.
26 Amaiba: le, ninia da Ea fidisu amola gaga: su lamusa: , gebewane mae momabone ouesalumu da defea.
Ó dára kí a ní sùúrù fún ìgbàlà Olúwa.
27 Amola amo hou ninia ayeligi amola afini eso amogainini dawa: mu da defea.
Ó dára fún ènìyàn láti gbé àjàgà nígbà tí ó wà ní èwe.
28 Ninia da se nabasea, ninisu ouiya: le esalumu da defea.
Jẹ́ kí ó jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, nítorí Olúwa ti fi fún un.
29 Ninia Hina Gode Ea sia: nabawane, begudumu da defea. Bai ninia da hobea misunu hou noga: idafa ba: ma: bela: le.
Jẹ́ kí ó bo ojú rẹ̀ sínú eruku— ìrètí sì lè wà.
30 Eno dunu da ninima fasea amola gadele sia: sea, ninia ouiya: le esalumu da defea.
Jẹ́ kí ó fi ẹ̀rẹ̀kẹ́ fún àwọn tí yóò gbá a, sì jẹ́ kí ó wà ní ìdójútì.
31 Hina Gode da ninima gogolema: ne olofosu dialebeba: le, E da nini hamedafa fisiagamu.
Ènìyàn kò di ìtanù lọ́dọ̀ Olúwa títí láé.
32 E da eso enoga ninima da: i diosu iaha, be Ea ninima asigisu hou da dafawanedafa amola gasa bagade.
Lóòtítọ́ ó mú ìbànújẹ́ wá, yóò fi àánú hàn, nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ̀.
33 E da da: i diosu amola se nabasu amo, Ea hanaiba: le ninima hame iaha.
Nítorí kò mọ̀ ọ́n mọ̀ mú ìpọ́njú wá tàbí ìrora wá fún ọmọ ènìyàn.
34 Ninia da se iasu diasu ganodini, da: i dioiwane esalea, Hina Gode da nini dawa: lala.
Láti tẹ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ gbogbo àwọn ẹlẹ́wọ̀n ní ilẹ̀ náà.
Láti ṣẹ́ ọmọ ènìyàn fún ẹ̀tọ́ rẹ̀ níwájú Ọ̀gá-ògo jùlọ,
36 Hina Gode da osobo bagade dunu ilia moloidafa fofada: su hou hamoma: ne ilegei. Be ninia amo hou hamobe hame ba: sea, E da dawa: lala.
láti yí ìdájọ́ ènìyàn padà, ǹjẹ́ Olúwa kò rí ohun bẹ́ẹ̀.
37 Hina Gode Ea hanai hou fawane da didili hahamona ahoana.
Ta ni yóò sọ̀rọ̀ tí yóò rí bẹ́ẹ̀ tí Olúwa kò bá fi àṣẹ sí i.
38 Hina Gode da logo doasibiba: le fawane, hou noga: i amola wadela: i ele defele doaga: sa.
Ǹjẹ́ kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá-ògo jùlọ ni rere àti búburú tí ń wá?
39 Ninia da wadela: i hou hamobeba: le, dawa: ma: ne se dabe iasu ba: sea, abuliga Godema egane sia: ma: bela: ?
Kí ló dé tí ẹ̀dá alààyè ṣe ń kùn nígbà tí ó bá ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀?
40 Ninia da ninia hamobe hou ba: lalu, Godema sinidigila: di!
Ẹ jẹ́ kí a yẹ ọ̀nà wa, kí a sì dán an wò, kí a sì tọ Olúwa lọ.
41 Ninia da ninia wadela: i hou hamoi Godema sisane fofada: nanu, noga: le amane sia: ne gadomu da defea.
Ẹ jẹ́ kí a gbé ọkàn àti ọwọ́ wa sókè sí Ọlọ́run ní ọ̀run, kí a wí pé,
42 “Ninia da wadela: le hamoi dagoi, amola Dima odoga: i. Amola Hina Gode! Di da ninia wadela: i hou hame gogolema: ne olofoi.
“Àwa ti ṣẹ̀ a sì ti ṣọ̀tẹ̀ ìwọ kò sì fi ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá.
43 Di da ninima sinidigili amola nini fane lelegei. Be Dia gogolema: ne olofosu hou amo da Dia ougi hou amoga dedeboi galu.
“Ìwọ fi ìbínú bo ara rẹ ìwọ sì ń lépa wa; ìwọ ń parun láìsí àánú.
44 Di da ninia sia: ne gadosu amo Dima mae doaga: ma: ne, Dia ougi hou da mu mobi agoane bagadedafa gadugagilisi.
Ìwọ ti fi àwọsánmọ̀ bo ara rẹ pé kí àdúrà wa má ba à dé ọ̀dọ̀ rẹ.
45 Di da nini osobo bagadega isu salasu agoane hamoi
Ó ti sọ wá di èérí àti ààtàn láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
46 Ninima ha lai dunu huluane da ninima gadesa amola oufesega: sa.
“Gbogbo àwọn ọ̀tá wa ti la ẹnu wọn gbòòrò sí wa.
47 Ninima gugunufinisisu da doaga: i dagoi. Ninia da se nabasa: besa: le bebeda: iya esafulu.
Àwa ti jìyà àti ìparun, nínú ìbẹ̀rù àti ewu.”
48 Na fi dunu ilima gugunufinisisu hou ba: beba: le, na si hano da hano defele dala.
Omijé ń sàn ní ojú mi bí odò nítorí a pa àwọn ènìyàn mi run.
49 Na si hano da hame hasu hano agoane daleawane,
Ojú mi kò dá fún omijé, láì sinmi,
50 Hina Gode da Hebene gadodili ninima ba: le gudusia, nini ba: sa.
títí ìgbà tí Olúwa yóò síjú wolẹ̀ láti òkè ọ̀run tí yóò sì rí i.
51 Na da moilai bai bagade ganodini fi uda, amo ilima hamoi amo ba: sea, Na da dogo faga: sa.
Ohun tí mo rí mú ìbẹ̀rù wá ọkàn mi nítorí gbogbo àwọn obìnrin ìlú mi.
52 Nama ha lai dunu ilia nama higabe da bai hame gala. Be dunu ilia da sio sanigebe defele, nama ha lai da na sa: ima: ne sani gei.
Àwọn tí ó jẹ́ ọ̀tá mi láìnídìí dẹ mí bí ẹyẹ.
53 Ilia da na esalumuna: wane uli gelaba sanasili, gelega gadodili ga: si.
Wọ́n gbìyànjú láti mú òpin dé bá ayé mi nínú ihò wọ́n sì ju òkúta lù mí.
54 Na da gudu esaloba hano da na dedebomusa: heda: beba: le, na bogomu gadenebeyale dawa: i.
Orí mi kún fún omi, mo sì rò pé ìgbẹ̀yìn dé.
55 Hina Gode! Na da uli dogoi gudu lela, na da Dima disa wele sia: i.
Mo pe orúkọ rẹ, Olúwa, láti ọ̀gbun ìsàlẹ̀ ihò.
56 Amola na da Dia fidima: ne dini iabe nabima: ne sia: beba: le, Di da na dibi nabi dagoi.
Ìwọ gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi, “Má ṣe di etí rẹ sí igbe ẹ̀bẹ̀ mi fún ìtura.”
57 Di da nama bu adole i, “Di mae beda: ma!”
O wá tòsí nígbà tí mo ké pè ọ́, o sì wí pé, “Má ṣe bẹ̀rù.”
58 Di da na esalusu gaga: musa: misini, na esaloma: ne hamoi.
Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi rò, o ra ẹ̀mí mi padà.
59 Hina Gode! Di da na wadela: le hamoi amo Di dawa: Dia fofada: nanu, na hou da moloidafa sia: ma.
O ti rí i, Olúwa, búburú tí a ṣe sí mi. Gba ẹjọ́ mi ró!
60 Dia dawa: ! Nama ha lai dunu da na higale, amola na medomusa: wamo sia: daha.
Ìwọ ti rí ọ̀gbun ẹ̀san wọn, gbogbo ìmọ̀ wọn sí mi.
61 Hina Gode! Ilia nama gadebe, amola na famusa: wamo sia: dabe, amo Dia dawa:
Olúwa ìwọ ti gbọ́ ẹ̀gàn wọn àti ìmọ̀ búburú wọn sí mi,
62 Hahabe ganini asili gasia, ilia da na hou amoga ilegele sia: daha amola na famusa: wamo sia: daha.
ohun tí àwọn ọ̀tá mi ń sọ sí mi ní gbogbo ọjọ́.
63 Hahabe ganini asili gasia, ilia da nama lalasogole oufesega: sa.
Wò wọ́n! Ní jíjòkòó tàbí ní dídìde, wọ́n ń ṣẹlẹ́yà mi nínú orin wọn.
64 Hina Gode! Ilia nama wadela: le hamobeba: le, ilima se dabe ima!
Olúwa san wọ́n lẹ́san ohun tí ó tọ́ sí wọn fún ohun tí ọwọ́ wọn ti ṣe.
65 Ilima gagabusu aligima: ne ilegema! Amola ili lobo hehealema: ne hamoma!
Fi ìbòjú bò wọ́n ní ọkàn, kí o sì fi wọ́n ré.
66 Ili osobo bagadega mae esaloma: ne, gala: la bobogema!
Ni wọ́n lára kí o sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìbínú, lábẹ́ ọ̀run Olúwa.

< Fofagini Disu 3 >