< Bisisu 8 >

1 Amalalu, Ifala: ime fi dunu da Gidionema amane sia: i, “Di da Midia: ne fi ilima gegemusa: ahoanoba, abuliba: le nini misa: ne hame wele sia: bela: ? Abuliba: le nini se nabima: ne agoane hamobela: ?” Ilia da da: i dione egai.
Àwọn àgbàgbà ẹ̀yà Efraimu sì bínú gidigidi sí Gideoni wọ́n bi í léèrè pé, kí ló dé tí o fi ṣe irú èyí sí wa? Èéṣe tí ìwọ kò fi pè wá nígbà tí ìwọ kọ́kọ́ jáde lọ láti bá àwọn ará Midiani jagun? Ohùn ìbínú ni wọ́n fi bá a sọ̀rọ̀.
2 Be Gidione da ilima bu adole i, “Mae dawa: ma! Dilia hamoi hou da na hamoi bagade baligisa. Dilia fidisu da na fi dunu huluane ilia fidisu amo bagade baligisa.
Ṣùgbọ́n Gideoni dá wọn lóhùn pé, “Àṣeyọrí wo ni mo ti ṣe tí ó tó fiwé tiyín? Àṣàkù àjàrà Efraimu kò ha dára ju gbogbo ìkórè àjàrà Abieseri lọ bí?
3 Dilia Gode Ea gasa lai dagoiba: le, Midia: ne ouligisu dunu aduna amo Oulebe amola Siebe fane legei dagoi. Na da dilia gasa bagade hou defele hamomu hamedei agoane ba: i.” E da amo sia: beba: le, Ifala: ime dunu ilia ougi bu gumi ba: i.
Ọlọ́run ti fi Orebu àti Seebu àwọn olórí àwọn ará Midiani lé yín lọ́wọ́. Kí ni ohun tí Mose ṣe tí ó tó fiwé e yín tàbí tí ó tó àṣeyọrí i yín?” Nígbà tí ó wí èyí ríru ìbínú wọn rọlẹ̀.
4 Gidione amola ea dadi gagui (ilia idi da 300) da Yodane Hano amoga doaga: le degei dagoi. Ilia da bagade helei ba: i, be mae fisili ilia ha lai dunu sefasilalu.
Gideoni àti àwọn ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ tẹ̀síwájú láti lépa àwọn ọ̀tá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti rẹ̀ wọ́n, wọ́n dé Jordani wọ́n sì kọjá sí òdìkejì.
5 Ilia da Sagode moilaiga doaga: loba, Gidione da Sagode dunu ilima amane sia: i, “Ha: i manu ninima ima. Na dunu da bagade helebe. Na da Midia: ne fi hina bagade dunu aduna amo Siba amola Sa: lamana sefasilala.”
Ó wí fún àwọn ọkùnrin Sukkoti pé, “Ẹ fún àwọn ọmọ-ogun mi ní oúnjẹ díẹ̀, nítorí ó ti rẹ̀ wọ́n, èmi sì ń lépa Seba àti Salmunna àwọn ọba Midiani.”
6 Be Sagode moilai ouligisu dunu da Gidionema bu adole i, “Ninia abuliba: le dia dadi gagui dunuma ha: i manu ima: bela: ? Di da wali Siba amola Sa: lamana hame gagui.”
Ṣùgbọ́n àwọn ìjòyè Sukkoti fèsì pé ṣé ọwọ́ rẹ ti tẹ Seba àti Salmunna náà ni? Èéṣe tí àwa yóò ṣe fún àwọn ológun rẹ ní oúnjẹ?
7 Amaiba: le, Gidione da amane sia: i, “Defea! Hina Gode da na fidimuba: le, na da Siba amola Sa: lamana gagumu. Amasea, na da dili aya: gaga: nomei hafoga: i sogega lai amoga famu.”
Gideoni dá wọn lóhùn pé, “Ó dára, nígbà tí Olúwa bá fi Seba àti Salmunna lé mi lọ́wọ́ tán èmi yóò fi ẹ̀gún ijù àti ẹ̀gún òṣùṣú ya ẹran-ara yín.”
8 Gidione da bu asili, Beniuele moilaiga doaga: i. E da Sagode moilai dunu amoga edegei defele Beniuele dunuma adole ba: i. Be Beniuele dunu da Sagode dunu ilia hou defele, ha: i manu hame imunu sia: i.
Láti ibẹ̀, ó lọ sí Penieli ó sì bẹ̀ wọ́n bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ṣùgbọ́n àwọn náà dá a lóhùn bí àwọn ará Sukkoti ti dá a lóhùn.
9 Amaiba: le, Gidione da ilima amane sia: i, “Defea! Na da na ha lai ili hasalasili, hahawane bu misunu. Amalalu, na da dilia diasu gado gagagula heda: i amo mugulumu.”
Nígbà náà ni ó sọ fún àwọn ọkùnrin Penieli pé, “Nígbà tí mo bá ṣẹ́gun tí mo sì padà dé ní àlàáfíà, èmi yóò wó ilé ìṣọ́ yìí.”
10 Siba amola Sa: lamana elea dadi gagui dunu huluane da Gago moilai bai bagadega gilisibi ba: i. Amo esoga, ilia hafoga: i soge dadi gagui dunu idi da 15,000 fawane ba: i. Eno dadi gagui dunu amo 120,000 da medole legei dagoi ba: i.
Ní àsìkò náà Seba àti Salmunna wà ní Karkori pẹ̀lú ọmọ-ogun wọn tí ó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ọkùnrin, àwọn wọ̀nyí ni ó ṣẹ́kù nínú gbogbo ogun àwọn ènìyàn apá ìlà-oòrùn, nítorí ọ̀kẹ́ mẹ́fà ọkùnrin tí ó fi idà jà ti kú ní ojú ogun.
11 Gidione da logo amo hafoga: i soge bega: Nouba moilai amola Yogebiha moilaiga eso mabadi la: ididili dialu, amo logoga asi. E da hedolowane Siba amola Sa: lamana ilia dadi gagui wa: i ilima doagala: le, ilia da fofogadigi.
Gideoni gba ọ̀nà tí àwọn darandaran máa ń rìn ní apá ìhà ìlà-oòrùn Noba àti Jogbeha ó sì kọjú ogun sí àwọn ọmọ-ogun náà nítorí wọ́n ti túra sílẹ̀.
12 Midia: ne hina bagade dunu aduna amo Siba amola Sa: lamana da hobea: i. Be Gidione da elama doagala: le bobogele, ela gagulaligi. Amalalu, ela dadi gagui dunu huluane da beda: iba: le, hobea: i
Seba àti Salmunna, àwọn ọba Midiani méjèèjì sá, ṣùgbọ́n Gideoni lépa wọn ó sì mú wọn, ó run gbogbo ogun wọn.
13 Gidione da hasaliba: le, bu misini, Helese fago ahoasu amoga asili,
Gideoni ọmọ Joaṣi gba ọ̀nà ìgòkè Heresi padà sẹ́yìn láti ojú ogun.
14 e da Sagode moilai goi amo gaguli, ema ea fi dunu ilia hou adole ba: i. Amo goi da Sagode moilai ouligisu dunu bagade 77amo ilia dio dedei.
Ó mú ọ̀dọ́mọkùnrin kan ará Sukkoti, ó sì béèrè àwọn ìbéèrè ní ọwọ́ rẹ̀, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì kọ orúkọ àwọn ìjòyè Sukkoti mẹ́tàdínlọ́gọ́rin fún un tí wọ́n jẹ́ àgbàgbà ìlú náà.
15 Amalalu, Gidione da Sagode dunu ilima asili, amane sia: i, “Siba amola Sa: lamana da goea. Na da amo dunu hame gaguiba: le, dilia da na dadi gagui dunu hele nababe, ilima ha: i manu imunu higa: i.”
Nígbà náà ni Gideoni wá ó sọ fún àwọn ọkùnrin Sukkoti pé, “Seba àti Salmunna nìwọ̀nyí nípa àwọn tí ẹ̀yin fi mí ṣẹ̀fẹ̀ nígbà tí ẹ wí pé, ‘Ṣé ó ti ṣẹ́gun Seba àti Salmunna? Èéṣe tí àwa ó fi fún àwọn ọmọ-ogun rẹ tí ó ti rẹ̀ ní oúnjẹ?’”
16 Amalalu e da hafoga: i soge aya: gaga: nomei liligi lale, amoga Sagode ouligisu dunu se ima: ne fasu.
Ó mú àwọn àgbàgbà ìlú náà, ó sì fi kọ́ àwọn Sukkoti lọ́gbọ́n nípa jíjẹ wọ́n ní yà pẹ̀lú àwọn ẹ̀gún ijù àti ẹ̀gún ọ̀gàn.
17 Amola e da diasu gagagula gado heda: i, Beniuele moilaiga mugululi amola Beniuele dunu medole legei dagoi.
Ó wó ilé ìṣọ́ Penieli, ó sì pa àwọn ọkùnrin ìlú náà.
18 Amalalu, Gidione da Siba amola Sa: lamana elama amane adole ba: i, “Alia da Da: ibo moilaiga dunu medole legei. Alia da nowa dunu medole legebela: ?” Ela bu adole i, “Ilia da di agoane ba: i. Huluane da hina bagade ea mano defele agoane ba: i.”
Gideoni bi Seba àti Salmunna pé, “Irú ọkùnrin tí ẹ pa ní Tabori, báwo ni wọ́n ṣe rí?” “Àwọn ọkùnrin náà dàbí rẹ ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn dàbí ọmọ ọba,” ní ìdáhùn wọn.
19 Gidione da amane sia: i, “Ilia da nolalalia galu, na: medafa ea mano. Na da dafawane sia: sa. Alia da amo hame medole legei ganiaba, na da ali amola hame medole legela: loba.”
Gideoni dáhùn pé, “Arákùnrin mi ni wọ́n, àwọn ọmọ ìyá mi. Mo fi Olúwa búra, bí ó bá ṣe pé ẹ dá ẹ̀mí wọn sí, èmi náà ò nípa yín.”
20 Amalalu, e da ea magobo mano ea dio amo Yeda, amoma amane sia: i, “Defea! Dia ela medole legema!” Be amo goi da ea gegesu gobihei bagade hame duga: le gagui. E da hame asigilaiba: le, beda: i.
Ó yí padà sí Jeteri, ọmọ rẹ̀ tí ó dàgbà jùlọ, ó wí fún un pé, “Pa wọ́n!” Ṣùgbọ́n Jeteri kò fa idà rẹ̀ yọ láti pa wọ́n nítorí ó jẹ́ ọ̀dọ́mọdé ẹ̀rù sì bà á láti pa wọ́n.
21 Amalalu, Siba amola Sa: lamana da Gidionema amane sia: i, “Defea! Disu ani medole legema. Dunudafa da dunudafa ea hawa: hamosu hamomu da defea.” Amaiba: le, Gidione da Siba amola Sa: lamana medole legei dagoi. E da liligi noga: i amo ela ga: mele ilia galogoa amoga gisa: gisi dialu amo lai dagoi.
Seba àti Salmunna dá Gideoni lóhùn pé, “Wá pa wá fún raàrẹ, ‘Nítorí bí ènìyàn bá ti rí bẹ́ẹ̀ ni agbára rẹ̀ yóò rí.’” Gideoni bọ́ síwájú ó sì pa wọ́n, ó sì mú ohun ọ̀ṣọ́ tí ó wà ní ọrùn àwọn ìbákasẹ wọn.
22 Amalalu, Isala: ili dunu huluane da Gidionema amane sia: i, “Di amola hobea digaga fi da ninima ouligisuwane esalumu da defea. Di da nini amo Midia: ne dunu iliga gaga: i dagoi.”
Àwọn ará Israẹli wí fún Gideoni pé, “Jọba lórí wa—ìwọ, àwọn ọmọ rẹ àti àwọn ọmọ ọmọ rẹ pẹ̀lú, nítorí tí ìwọ ti gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Midiani.”
23 Be Gidione da bu adole i, “Na da dilima ouligisuwane hame esalumu. Amola nagofe da dilima ouligisuwane hame esalumu. Be Hina Gode Hi fawane da dilima Hina ba: mu.”
Ṣùgbọ́n Gideoni dá wọn lóhùn pé, “Èmi kì yóò jẹ ọba lórí yín, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ mi kì yóò jẹ ọba lórí yín. Olúwa ni yóò jẹ ọba lórí yín.”
24 E da eno amane sia: i “Na da dilima afae fawane edegesa. Dilia gedu bagedigi Midia: ne dunu ilima lai, amo huluane nama ima.” (Midia: ne dunu da hafoga: i soge dunu fi huluane defele gouli gedu bagedigili salasu.)
Gideoni sì wí pé, “Mo ní ẹ̀bẹ̀ kan tí mo fẹ́ bẹ̀ yín kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín fún mi ní yẹtí kọ̀ọ̀kan láti inú ohun ti ó kàn yín láti inú ìkógun.” (Àṣà àwọn ará Iṣmaeli ni láti máa fi yẹtí wúrà sétí.)
25 Dunu huluane da bu adole i, “Ninia da hahawane amo liligi dima imunuyo.” Ilia da abula ligisili, dunu huluane da amo da: iya geabagedigisu ilia lai ligisi.
Wọ́n dáhùn pé, “Tayọ̀tayọ̀ ni àwa yóò fi wọ́n sílẹ̀.” Wọ́n tẹ́ aṣọ kan sílẹ̀ ọkùnrin kọ̀ọ̀kan sì ń sọ yẹtí kọ̀ọ̀kan tí ó kàn wọ́n láti ibi ìkógun síbẹ̀.
26 Gidione da gouli gedu bagedigi lai dagoi. Ilia dioi defei da 210 gilogala: me gadenene doaga: i. Ilia da eno liligi Gidionema i, amo bagedigi, gisa: gini sali amola ogaya: i abula musa: Midia: ne hina bagade dunu da gasi salasu amola gehea: la ilia da ga: mele ea galogoa ga: si.
Ìwọ̀n òrùka wúrà tí ó béèrè fún tó ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀sán ìwọ̀n ṣékélì, láìka àwọn ohun ọ̀ṣọ́ àti ohun sísorọ̀ tí ó wà lára ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn àti aṣọ elése àlùkò tí àwọn ọba Midiani ń wọ̀ tàbí àwọn ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní ọrùn àwọn ìbákasẹ wọn.
27 Gidione da amo gouli lale, ogogosu ‘gode’ agoaila loboga hamone, ea moilaidafa Ofala amo ganodini bugisi. Isala: ili dunu huluane iliawa da Gode fisili, Ofala moilai bai bagadega amo loboga hamoi liligima sia: ne gadomusa: asi. Amo liligi da Gidione amola ea sosogo fi ilima sani agoane ba: i.
Gideoni fi àwọn wúrà náà ṣe efodu èyí tí ó gbé kalẹ̀ ní Ofira ìlú rẹ̀. Àwọn ọmọ Israẹli sì sọ ara wọn di àgbèrè nípa sínsin-ín ní ibẹ̀. Ó sì di ìdẹ̀kùn fún Gideoni àti ìdílé rẹ̀.
28 Amaiba: le, Isala: ili dunu da Midia: ne dunu ili hasalasi amola fa: no Midia: ne dunu da gasa hame ba: i. Amalalu, ode 40 eno amoga, Isala: ili dunu da olofosu ba: i. Amo ode 40 gidigili, Gidione da bogoi dagoi.
Báyìí ni a ṣe tẹrí àwọn ará Midiani ba níwájú àwọn ọmọ Israẹli bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tún gbé orí mọ́. Ní ọjọ́ Gideoni, Israẹli wà ní àlàáfíà fún ogójì ọdún.
29 Gidione da hina: moilaidafa amoga buhagili esalu.
Jerubbaali ọmọ Joaṣi padà lọ láti máa gbé ní ìlú rẹ̀.
30 E da uda bagohame lale, dunu mano 70agoane lalelegei.
Àádọ́rin ọmọ ni Gideoni bí, nítorí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìyàwó.
31 E da uda eno lai. Amo da gidisedagi uda e da Siegeme moilaiga lai. Amo uda da dunu mano lalelegei. Gidione da amo manoma Abimelege dio asuli.
Àlè rẹ̀, tó ń gbé ní Ṣekemu, pàápàá bí ọmọkùnrin kan fún un tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní Abimeleki.
32 Gidione (Youa: se egefe) da ode bagohame gidigili bogoi. Ilia da ea da: i hodo amo ea eda Youa: se ea bogoi uli dogosu Ofala moilai bai bagade (Abiese fi ilia moilai) amoga dialu, amo ganodini sali.
Gideoni ọmọ Joaṣi kú ní ògbólógbòó ọjọ́ rẹ̀, ó sì pọ̀ ní ọjọ́ orí, wọ́n sì sin ín sí ibojì baba rẹ̀ ní Ofira ti àwọn ará Abieseri.
33 Gidione da bogoloba, Isala: ili dunu ilia da bu Gode fisili, Ba: ile ema nodone sia: ne gadoi. Ilia da ema ‘Ba: ile da Gousa: su Hamoi’ dio asuli, amola e da ilia ‘gode’dafa ilia da sia: su.
Láìpẹ́ jọjọ lẹ́yìn ikú Gideoni ni àwọn ará Israẹli ṣe àgbèrè tọ Baali lẹ́yìn, wọ́n fi Baali-Beriti ṣe òrìṣà wọn.
34 Ilia Hina Godedafa da ilima sisiga: i ha lai dunu ilima gaga: i dagoi. Be amo mae dawa: le, ilia da Hina Godema hawa: hamosu yolesi dagoi.
Wọn kò sì rántí Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni tí ó gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn gbogbo tí ó wà ní gbogbo àyíká wọn.
35 Amola Gidione da Isala: ili dunu fidima: ne, hawa: hamosu ida: iwane hamoi. Be ilia da Gidione ea sosogo fi ilima hame nodoi.
Wọ́n kùnà láti fi inú rere hàn sí ìdílé Jerubbaali (èyí ni Gideoni) fún gbogbo oore tí ó ṣe fún wọn.

< Bisisu 8 >