< Bisisu 6 >

1 Isala: ili dunu ilia da Hina Godema bu wadela: le hamoi. Amaiba: le, E da Midia: ne dunu ilia Isala: ili dunu ode fesuale amoga wadela: lesima: ne logo doasi dagoi.
Àwọn ọmọ Israẹli sì túnṣe ohun tí ó burú ní ojú Olúwa, Ó sì fi wọ́n lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́ fún ọdún méje.
2 Midia: ne fi dunu ilia gasa da Isala: ili fi ilia gasa baligi. Amaiba: le, Isala: ili fi dunu da magufu gelabo amola eno wamoaligisu sogebi agolo ganodini amoga wamoaligisu.
Agbára àwọn ará Midiani sì pọ̀ púpọ̀ lórí àwọn Israẹli, wọ́n sì hùwà ipá sí wọn, nítorí ìdí èyí, àwọn Israẹli sálọ sí àwọn orí òkè, wọ́n sì kọ́ àgọ́ fún ara wọn nínú ihò àpáta, àti nínú ọ̀gbun àti ní ibi agbára nínú àpáta.
3 Eso huluane, Isala: ili fi dunu da hawa: sagaloba, Midia: ne fi dunu, A:malege fi dunu amola eno hafoga: i sogega fi dunu da gilisili ilima doagala: le gegesu.
Ní ìgbàkúgbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá ti gbin ọ̀gbìn wọn, àwọn ará Midiani, àwọn ará Amaleki àti àwọn ará ìlà-oòrùn mìíràn yóò wá láti bá wọn jà.
4 Ilia da hou agoane hamosu. Ilia da Isala: ili soge amoga fisisu. Amalalu, ilia da Isala: ili dunu ilia sagai amo fana asili, gugaga asili, Ga: isa moilaiga doaga: su. Ilia da Isala: ili dunu ilia sibi, bulamagau amola dougi wamolalusu. Amaiba: le, Isala: ili dunu da liligi hamedene esalusu.
Wọn yóò tẹ̀dó sí orí ilẹ̀ náà, wọn a sì bá irúgbìn wọ̀nyí jẹ́ títí dé Gasa, wọn kì í sì í fi ohun alààyè kankan sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli, kì bá à ṣe àgùntàn, màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
5 Midia: ne dunu bagohame ilia idi da danuba: wa: i defele ba: i, ilia da Isala: ili soge amoga ilia ohe fi oule misini, ilia abula diasu gagusu. Ilia amola ilia ga: mele da idimu hamedeiwane ba: i. Ilia da misini, soge huluane wadela: lesisu.
Wọn a máa wá pẹ̀lú ohun ọ̀sìn wọn àti àwọn àgọ́ wọn, wọn a sì dàbí eṣú nítorí i púpọ̀ wọn. Ènìyàn kò sì lè ka iye àwọn ènìyàn náà bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìbákasẹ, wọ́n pọ̀ dé bi pé wọn kò ṣe é kà ní iye, wọn a bo ilẹ̀ náà wọn a sì jẹ ẹ́ run.
6 Isala: ili dunu da gasa hameba: le, ilia logo hedofamusa: gasa bagade ba: i.
Àwọn ará Midiani sì pọ́n àwọn ọmọ Israẹli lójú, wọ́n sọ wọ́n di òtòṣì àti aláìní, fún ìdí èyí wọ́n ké pe Olúwa nínú àdúrà fún ìrànlọ́wọ́.
7 Amalalu, Isala: ili dunu da se nababeba: le, Hina Godema wele sia: i. Ilia da Gode Ea fidima: ne, Midia: ne dunu ilia logo hedofama: ne wele sia: i.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ké pe Olúwa nítorí àwọn ará Midiani.
8 Hina Gode da ilima balofede dunu asunasi. Balofede dunu e da ilima amane sia: i, “Isala: ili fi dunu ilia Hina Gode da amane sia: sa, ‘Dilia da hemonega Idibidi soge ganodini udigili lobo lala: gi agoai hawa: hamonanu. Be Na da dili fisili masa: ne gadili oule asi.
Olúwa fi etí sí igbe wọn, ó sì rán wòlíì kan sí wọn, ẹni tí ó wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: mo mú yín gòkè ti Ejibiti wá, láti oko ẹrú.
9 Idibidi dunu da dili mae wadela: ma: ne, Na da dili gaga: i. Amola Ga: ina: ne sogega fi dunu da dili mae wadela: ma: ne, Na da dili gaga: i. Dilia da gusuba: i heda: loba, Na da amo dunu sefasisu. Amola Na da ilia soge amo dilima i dagoi.
Mo gbà yín kúrò nínú agbára Ejibiti àti kúrò ní ọwọ́ gbogbo àwọn aninilára yín. Mo lé wọn kúrò ní iwájú yín, mo sì fi ilẹ̀ wọn fún yín.
10 Na da dilia Hina Godedafa, amo Na da dilima olelei. Amola dilia da A: moulaide dunu, (dilia wali ilia soge ganodini esala) amo ilia ogogosu ‘gode’ liligi ilima mae sia: ne gadoma: ne, Na da sia: i dagoi. Be dilia da Na sia: hame nabi.’”
Mo wí fún un yín pé, ‘Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín; ẹ má ṣe sin àwọn òrìṣà àwọn ará Amori, ní ilẹ̀ ẹni tí ẹ̀yin ń gbé.’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọ́rọ̀ sí ohun tí mo sọ.”
11 Amalalu, Hina Gode Ea a: igele dunu da Ofala moilai bai bagadega misini, “ouge” ifa amo ea ougiha esalu. Amo ifa da Youa: se (A: ibisa fi dunu) amo ea ifa falifai galu. Youa: se egefe Gidione da Midia: ne dunu ilia ba: sa: besa: le, wamowane widi ha: i manu gisi amo afafama: ne, waini hano hamosu diasu amo ganodini widi gisi dabalebe ba: i.
Ní ọjọ́ kan angẹli Olúwa wá, ó sì jókòó ní abẹ́ igi óákù Ofira èyí ti ṣe ti Joaṣi ará Abieseri, níbi tí Gideoni ọmọ rẹ̀ ti ń lu ọkà jéró, níbi ìpọntí wáìnì láti fi pamọ́ kúrò níwájú àwọn ará Midiani.
12 Hina Gode Ea a: igele dunu da ema misini, amane sia: i, “Gasa bagade nimi dunu! Hina Gode da ali esala.”
Nígbà tí angẹli Olúwa fi ara han Gideoni, ó wí fún un pé, “Olúwa wà pẹ̀lú rẹ, akọni ológun.”
13 Gidione da bu adole i, “Na da dima adole ba: mu gala. Hina Gode da nini esala, di da sia: sa. Amaiba: le amo se nabasu da abuliba: le ninima doaga: bela: ? Ninia ada ilia da Hina Gode Ea gasa bagade hou amo ninima olelei. E da Idibidi sogega nini fisili masa: ne gadili asunasi. Be wali Hina Gode da Midia: ne dunu nini wadela: lesima: ne, fisi dagoi.”
Gideoni dáhùn pé, “Alàgbà, bí Olúwa bá wà pẹ̀lú wa, kí ló dé tí gbogbo ìwọ̀nyí fi ń ṣẹlẹ̀ sí wa? Níbi gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ tí àwọn baba wa ròyìn rẹ̀ fún wa nígbà tí wọ́n wí pé, ‘Olúwa kò ha mú wa gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá?’ Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa ti kọ̀ wá sílẹ̀, ó sì ti fi wá lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́.”
14 Amalalu, Hina Gode da Gidione ea hamoma: ne, ema amane olelei, “Dina: gasaga masa! Midia: ne dunu ilia Isala: ili fi mae wadela: ma: ne, di gaga: ma! Na Nisu fawane, da di asunasisa.”
Olúwa sì yípadà sí i, ó sì wí fún un pé, “Lọ nínú agbára tí o ní yìí, kí o sì gba àwọn ará Israẹli sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Midiani. Èmi ni ó ń rán ọ lọ.”
15 Gidione da bu adole i, “Na da habodane Isala: ili fi gaga: ma: bela: ? Na sosogo fi da Mana: se fi amo ganodini gogaya: i gala. Amola na da na sosogo fi amo ganodini bodogidafa.”
Gideoni sì dáhùn pé, “Yéè olúwa mi, ọ̀nà wo ni èmi yóò fi gba Israẹli là? Ìdílé mi ni ó jẹ́ aláìlera jù ní Manase, àti pé èmi ni ó sì kéré jù ní ìdílé baba mi.”
16 Hina Gode da ema bu adole i, “Na da di fidimuba: le, di da amo hamomusa: dawa: mu. Di da Midia: ne dunu huluane hasalili dagomu.”
Olúwa sì dáhùn pé, “Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ, ìwọ yóò sì pa gbogbo àwọn ará Midiani láì ku ẹnìkankan.”
17 Gidione ea bu adole i, “Di da nama nodosa galea, na da Di dafawane Hina Gode esala, amo dawa: ma: ne, dawa: digisu hou amo nama olelema.
Gideoni sì dáhùn pé, nísinsin yìí tí mo bá bá ojúrere rẹ pàdé, fún mi ní àmì pé ìwọ ni ń bá mi sọ̀rọ̀.
18 Dafawane! Di da na mae yolesili ouleloma. Na da Dima gobele salasu ha: i manu gaguli misunu,” Gidione amane sia: i. Hina Gode Ea amane sia: i, “Na da di ouesalea, amogainini di bu misunu.”
Jọ̀wọ́ má ṣe kúrò níbí títí èmi yóò fi mú ọrẹ wá fún ọ kí n sì gbé e sí iwájú rẹ. Olúwa sì wí pé, “Èmi yóò dúró títí ìwọ yóò fi dé.”
19 Amaiba: le, Gidione da hi diasua golili sa: ili, goudi mano sefena afae fane, falaua ea dioi defei da10gilougala: me amo lale, yisidi mae legele, agi ga: gi hamoi. E da goudi hu dabaga salawane, gugu gasa: le, ofodo ganodini salawane, gaguli, Hina Gode a: igele dunu “ouge” ifa baiya lelebe amogili iasi.
Gideoni sì yára wọ ilé lọ, ó sì pa ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan, wọ́n sì sè é, ó sì mú ìyẹ̀fun efa kan, ó fi ṣe àkàrà aláìwú. Ó gbé ẹran náà sínú agbọ̀n, ṣùgbọ́n ó fi ọbẹ̀ rẹ̀ sínú ìkòkò, ó gbé wọn jáde tọ angẹli náà wá bí ọrẹ lábẹ́ igi óákù.
20 A: igele dunu da Gidionema amane sia: i, “Hu amola agi ga: gi lale, igi goe da: iya ligisili, amo da: iya gugu soga: sima.” Gidione da amo defele hamoi dagoi.
Angẹli Ọlọ́run náà sì wí fún un pé, “Gbé ẹran náà àti àkàrà àìwú náà, sí orí àpáta yìí, kí o sì da omi ọbẹ̀ rẹ̀ sí orí rẹ̀.” Gideoni sì ṣe bẹ́ẹ̀.
21 Amalalu, Hina Gode Ea a: igele dunu da ea lobo ligiagale, galiamo ea lobo ganodini gagui, amo ea bidiga, e da hu amola agi ga: gi digilisi. Amalalu, lalu da igi da: iya wiligadole, hu amola agi ga: gi nene dagoi. Amalalu, a:igele dunu da asi, hame ba: i.
Angẹli Olúwa sì fi orí ọ̀pá tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀ kan ẹran àti àkàrà àìwú náà. Iná sì jáde láti inú àpáta, ó sì jó ẹran àti àkàrà náà, kò sì rí angẹli náà mọ́.
22 Amaiba: le, Gidione hamugini ba: loba, amo da Hina Gode ea a: igele dunu dawa: i galu. Amola e da bagadewane fofogadigili, beda: ne amane sia: i, “Hina Gode Bagadedafa! Na da Dia a: igele dunu ea odagi amola na odagi migadenei ba: i.”
Nígbà tí Gideoni sì ti mọ̀ dájúdájú pé angẹli Olúwa ni, ó ké wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Mo ti rí angẹli Olúwa ní ojúkorojú!”
23 Hina Gode da ema amane sia: i, “Asaboma! Mae beda: ma! Di da hame bogomu.”
Ṣùgbọ́n Olúwa wí fún un pé, “Àlàáfíà! Má ṣe bẹ̀rù, ìwọ kì yóò kùú.”
24 Gidione da Godema gobele salasu fafai (oloda) amogawi gagui. Amoga, e da amo dio asuli, “Hina Gode da Olofosudafa.” Amo fafai da wali Ofala moilai bai bagadega sagasi dana. (Ofala da A: ibisa fi dunu ilia moilai eno galu).
Báyìí ni Gideoni mọ pẹpẹ kan fún Olúwa níbẹ̀, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní “Àlàáfíà ni Olúwa.” Ó sì wà ní Ofira ti Abieseri títí di òní.
25 Amo gasia, Hina Gode da Gidionema amane sia: i, “Dia ada ea bulamagau gawali amola eno bulamagau gawali ode fesuale gala lela, amo lama. Dia ada ea gobele salasu fafai Ba: ilema sia: ne gadomusa: gagui, amo mugululi salima. Amola ogogosu ‘gode’ ifaga hahamoi uda Asila, amola Ba: ile, ela dafulili lelebe go abasalima.
Ní òru ọjọ́ náà Olúwa wí fún un pé, mú akọ màlúù baba rẹ, àní akọ màlúù kejì ọlọ́dún méje. Wó pẹpẹ Baali baba rẹ lulẹ̀, kí o sì bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ lulẹ̀.
26 Dia Hina Godema gobele salasu fafai noga: idafa, goe bi da: iya gaguma. Amalu bulamagau gawali ageyadu e lale, ea da: i hodo huluane gobele salima. Amo gobele salimusa: di Asila ifa abasali lalu amoga lale didili gobele salima.”
Lẹ́yìn èyí kí o wá mọ pẹpẹ èyí tí ó yẹ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ lórí òkè yìí. Kí o sì mú akọ màlúù kejì, kí o sì mú igi ère òrìṣà Aṣerah tí ìwọ bẹ́ lulẹ̀ rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
27 Amaiba: le, Gidione ea hawa: hamosu dunu mogili, nabuane agoane lale, amola e da Hina Gode Ea ema adoi amo hamoi. E da ea sosogo fi amola ea moilai fi ilima beda: iba: le, yoga hamomu hamedei ba: i. Amaiba: le, e da gasia fawane hamoi.
Gideoni mú mẹ́wàá nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó sì ṣe bí Olúwa ti pàṣẹ fún un ṣùgbọ́n, nítorí ó bẹ̀rù àwọn ará ilé baba rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ìlú náà kò ṣe é ní ọ̀sán, òru ni ó ṣe.
28 Moilai fi dunu da hahabedafa wa: legadole, ilia da gobele salasu fafai Ba: ilema sia: ne gadomusa: gagui, amola Asila ea ifa abasali dagoi ba: i. Amola bulamagau ageyadu amo da gobele salasu fafai (Gidione ea gagui liligi) amo da: iya gobele sali dagoi, ilia ba: i.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, tí àwọn ènìyàn ìlú náà jí, wọ́n rí i pé àti fọ́ pẹpẹ Baali àti pé a ti bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, a sì ti fi akọ màlúù kejì rú ẹbọ lórí pẹpẹ tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ.
29 Amalalu, ilia amane sia: i, “Nowa dunu da amo hou hamobela: ? Ilia amane lalabilaloba, Youa: se ea mano Gidione ea hamoi, ilia ba: i.
Àwọn ènìyàn ìlú náà bi ara wọn wí pé, “Ta ni ó ṣe èyí?” Lẹ́yìn tí wọn fi ara balẹ̀ ṣe ìwádìí, wọ́n gbọ́ wí pé, “Gideoni ọmọ Joaṣi ni ó ṣe é.”
30 Amalalu, ilia da Youa: sema amane sia: i, “Diagofe ninia fane legemusa: guiguda: oule misa. E da Ba: ile gobele salasu fafai amo mugululi sali amola Asila hou dawa: ma: ne liligi amoga dafulili dialu amo abasali.”
Àwọn ọkùnrin ìlú náà sì wí fún Joaṣi wí pé, “Mú ọmọ rẹ jáde wá. Ó ní láti kú nítorí pé ó ti wó pẹpẹ Baali lulẹ̀ ó sì ti ké ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀bá rẹ̀ lulẹ̀.”
31 Be Youa: se da dunu huluane ilia da ema fofada: nanu, ilima amane sia: i, “Dilia da Ba: ile amoma gasala: ? Dilia amola e gaga: sala: ? Nowa da ema gale lela, amo da hahabe fane legei dagoi ba: mu. Ba: ile da Godedafa galea, defea, e da hisu hina: gaga: mu. Amo gobele salasu fafai mugululi sali da ea: liligi fawane, dilia: hame.”
Ṣùgbọ́n Joaṣi bi àwọn èrò tí wọ́n fi ìbínú dúró tì í wí pé, “Ẹ̀yin yóò ha gbìjà Baali bí? Ẹ̀yin yóò ha gbà á sílẹ̀ bí? Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbìjà rẹ̀ kíkú ni olúwa rẹ̀ yóò kú ní òwúrọ̀. Bí Baali bá ṣe Ọlọ́run nítòótọ́ yóò jà fún ara rẹ̀ bí ẹnikẹ́ni bá wó pẹpẹ rẹ̀ lulẹ̀.”
32 Amalalu, amohaga amola fa: no ilia da Gidione ea dio da Yeluba: ile, ilia da amane sia: dasu. Bai Youa: se da amane sia: i, “Ba: ile ea da hisu hina: gaga: mu da defea. Gobele salasu fafai mugululi sali da ea: liligi fawane.”
Fún ìdí èyí ní ọjọ́ náà wọ́n pe Gideoni ní “Jerubbaali” wí pé, “Jẹ́ kí Baali bá a jà,” nítorí pé ó ti wó pẹpẹ Baali.
33 Amalalu, Midia: naide fi dunu, A:malege fi dunu amola hafoga: i sogega fi dunu huluane gilisili mogodigili asili, Yodane hano amo degele, Yeseliele fago amogai hawa: i fisu.
Láìpẹ́ jọjọ, àwọn ogun àwọn Midiani, ti àwọn Amaleki àti ti àwọn ènìyàn ìhà ìlà-oòrùn yòókù kó ara wọn jọ pọ̀ ní ìṣọ̀kan, wọ́n sì kọjá Jordani wọ́n sì tẹ̀dó sí àfonífojì Jesreeli.
34 Hina Gode Ea A: silibu da Gidione amoma noga: le seselalu, A:ibisa sosogo fi dunu ilia ema fa: no bobogema: ne, Gidione da dalabede fulaboi.
Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé Gideoni, ó sì fun fèrè ìpè, láti pe àwọn ará Abieseri láti tẹ̀lé òun.
35 E da sia: adola ahoasu dunu ilia Mana: se fi dunu da ema fa: no bobogema: ne, adole lama: ne asunasi. E da sia: adola ahoasu dunu A: sie, Sebiulane amola Na: fadalai amo fi dunu ilima adoma: ne asunasi. Amalu, ilia misini, ema madelai.
Ó rán àwọn oníṣẹ́ la ilẹ̀ Manase já pé kí wọ́n dira ogun, àti sí Aṣeri, Sebuluni àti Naftali gbogbo pẹ̀lú sì lọ láti pàdé wọn.
36 Amalalu, Gidione da Godema amane sia: i, “Dia da amane sia: ba: , Isala: ili fi gaga: ma: ne, Dia da nama fidisu imunu sia: i.
Gideoni wí fún Ọlọ́run pé, “Bí ìwọ yóò bá gba Israẹli là nípasẹ̀ mi bí ìwọ ti ṣe ìlérí—
37 Defea! Na da sibi hinabo houga: i amo houga: i widi dabasu osobo da: iya amogai ligisimu. Be hahabe sibi hinabo houga: i da: iya oubi baeaga nanegai galea, be osobo da: iya da oubi baea hame ba: lalu, Isala: ili dunu fi amo na gaga: ma: ne, Dia da dafawane fidimusa: ilegei, amo na da dawa: mu.”
kíyèsi, èmi yóò fi awọ irun àgùntàn lé ilẹ̀ ìpakà ní alẹ́ òní. Bí ìrì bá sẹ̀ sí orí awọ yìí nìkan tí gbogbo ilẹ̀ yòókù sì gbẹ, nígbà náà ni èmi yóò mọ̀ lóòótọ́ pé ìwọ yóò gba Israẹli là nípasẹ̀ mi bí ìwọ ti sọ.”
38 Goe da didili agoane hamoi ba: i. Golale hahabedafa Gidione da wa: legadole, e da ofodo lale ligisili, sibi hinabo houga: i amo lale, oubi baea sibi hinaboga nanegai dialu amo ofodo gelaba ganodini dugini sali. Ofodo da amo hanoga nabaidafa ba: i.
Èyí ni ó sì ṣẹlẹ̀. Nígbà tí Gideoni jí ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì fún irun àgùntàn náà, ọpọ́n omi kan sì kún.
39 Amalalu, Gidione da Hina Godema amane sia: i, “Hina Gode! Dia nama mae ougima. Na da adoba: su afadafa eno hamomu da defeala: ? Be ha afaega musa: agoane hamosea, sibi hinabo houga: i da hafoga: i amola osobo da nanegai agoane ba: mu da defea.”
Gideoni sì tún wí fún Ọlọ́run pé, “Jọ̀wọ́ má ṣe bínú sí mi, ṣùgbọ́n jẹ́ kí n tún wá ìdánilójú kan sí i, èmi bẹ̀ ọ́ jẹ́ kí n fi awọ irun yìí ṣe ìdánwò kan sí i. Ní àsìkò yìí, jẹ́ kí awọ irun yìí gbẹ kí gbogbo ilẹ̀ sì tutù pẹ̀lú ìrì.”
40 Amo gasia Gode da amo liligi didiliwane hamoi. Golale hahabe, sibi hinabo houga: i da hafoga: i ba: i, be osobo da oubi baeaga nanegai dialebe ba: i.
Ní òru náà Ọlọ́run ṣe bẹ́ẹ̀, awọ irun àgùntàn nìkan ni ó gbẹ; gbogbo ilẹ̀ yòókù sì tutù nítorí ìrì.

< Bisisu 6 >