< Bisisu 15 >
1 Fa: no agoane widi faimu esoga, Sa: masane da ea uda ba: la asi. E da goudi mano ema imunusa: gaguli asi. E da amo uda ea ada ema amane sia: i, “Na da na uda ea diasuga golili sa: imu.” Be eda da mae masa: ne sia: i.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ní àkókò ìkórè alikama, Samsoni mú ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan láti bẹ ìyàwó rẹ̀ wò. Ó ní, “Èmi yóò wọ yàrá ìyàwó mi lọ.” Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ kò gbà á láààyè láti wọlé.
2 E da Sa: masane ema amane sia: i, “Na da dia nadiwi dafawane higa: i amo dawa: iou. Amaiba: le, na da e amo dia dogolegei ema i dagoi. Be di da ea eya a: fini noga: idafa lamu da defea.”
Baba ìyàwó dá a lóhùn pé, “Ó dá mi lójú pé o kórìíra rẹ̀, torí náà mo ti fi fún ọ̀rẹ́ rẹ, ṣe bí àbúrò rẹ̀ obìnrin kò ha lẹ́wà jùlọ? Fẹ́ ẹ dípò rẹ̀.”
3 Be Sa: masane da ougili amane sia: i, “Defea! Na da wali Filisidini dunuma mae dawa: le gasa bagade hamomu.”
Samsoni dáhùn pé, “Ní àkókò yìí tí mo bá ṣe àwọn Filistini ní ibi èmi yóò jẹ́ aláìjẹ̀bi.”
4 Amaiba: le, e da asili, fogisi 300 agoane gagadole lai. E da fogisi aduna aduna la: goga gilisili la: gili, ilia la: gisu bagele amoga hanu bagesi.
Samsoni sì jáde lọ, ó mú ọ̀ọ́dúnrún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ó so ìrù wọn mọ́ ara wọn ní méjì méjì. Ó mú ètùfù iná, ó so ó mọ́ àwọn ìrù tí ó so pọ̀.
5 Amalalu, e da hanu ulagisili, fogisi da Filisidini ilia gagoma ifabi amoga masa: ne asunasisiagai. E da amo hou hamobeba: le, Filisidini dunu ilia gagoma hame fai dialu, amola olife ifa huluane laluga nene dagoi ba: i.
Ó fi iná ran àwọn ètùfù tí ó so náà, ó sì jọ̀wọ́ wọn lọ́wọ́ lọ sínú àwọn oko ọkà àwọn Filistini. Ó jó àwọn pòpóòrò ọkà tí ó dúró àti àwọn tí a dì ní ìtí, ìtí, pẹ̀lú àwọn ọgbà àjàrà àti olifi.
6 Filisidini dunu ilia da amo hou nowa da hamobela: adole ba: loba, ilia da Sa: masane da hamoi sia: i nabi. Bai Dimina dunu amo esoa: da ea udalai amo samogene, ea dogolegei ema i dagoiba: le. Amalalu, Filisidini dunu da amo uda lale, medole laluga gobesi. Amola ilia da ea ada diasu laluga ulagili sali.
Nígbà tí àwọn Filistini béèrè pé, “Ta ni ó ṣe èyí?” Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Samsoni ará Timna ni, nítorí a gba ìyàwó rẹ̀ fún ọ̀rẹ́ rẹ̀.” Nítorí náà àwọn Filistini lọ wọ́n sì sun obìnrin náà àti baba rẹ̀.
7 Sa: masane da ilima amane sia: i, “Dilia da hou agoane hamonanebeba: le, na da Gode ba: ma: ne dafawane sia: sa. Na da mae fisidigili, dilima dabe imunu.”
Samsoni sọ fún un pé, “Nítorí pé ẹ̀yin ṣe èyí, èmi ó gbẹ̀san lára yín, lẹ́yìn náà èmi yóò sì dẹ́kun.”
8 E da ilima doagala: le, bagohame medole legei. Amalalu, e da asili, magufu gelabo Ida: me gafulu ganodini galu, amo ganodini esalu.
Ó kọlù wọ́n pẹ̀lú ìbínú àti agbára ńlá, ó sì pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wọn. Lẹ́yìn náà ni ó lọ, ó sì dúró nínú ihò àpáta kan nínú àpáta Etamu.
9 Filisidini dunu da misini, ilia hawa: i fisu Yuda soge ganodini gaguli esalu. Amalalu, ilia da Lihi sogega doagala: i.
Àwọn ará Filistini sì dìde ogun sí Juda, wọ́n ti tan ara wọn ká sí agbègbè Lehi.
10 Yuda dunu da ilima amane adole ba: i, “Dilia da abuliba: le ninima doagala: sala: ?” Ilia da bu adole i, “Ninia da Sa: masane amo afugili lale, ea hou ninima hamoi amo defele, ema agoane hamomusa: misi dagoi.”
Àwọn ọkùnrin Juda sì béèrè pé, “Èéṣe tí ẹ fi wá gbóguntì wá?” Ìdáhùn wọn ni pé, “A wá láti mú Samsoni ní ìgbèkùn, kí a ṣe sí i bí òun ti ṣe sí wa.”
11 Amaiba: le, Yuda dunu 3,000 da Ida: me gafulu ganodini magufu gelabo amoga asili, Sa: masane ema amane sia: i, “Filisidini dunu da ninia ouligisu dunu. Amo di da hame dawa: bela: ? Di da abuliba: le amo hou ninima hamobela: ?” Sa: masane da bu adole i, “Na da ilia hamoi amo dabe fawane bu dabe ga: i.”
Nígbà náà ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin láti Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí ihò àpáta nínú àpáta Etamu, wọ́n sì sọ fún Samsoni pé, “Kò ti yé ọ pé àwọn Filistini ní ń ṣe alákòóso lórí wa? Kí ni o ṣe sí wa?” Òun sì dáhùn pé, “Ohun tí wọ́n ṣe sí mi ni èmi náà ṣe sí wọn.”
12 Ilia da amane sia: i, “Ninia da di afugili la: gili ilima ima: ne misi dagoi.” Sa: masane da ilima amane sia: i, “Dilisu da na hame medole legemu, amo nama dafawane sia: ma.”
Wọ́n wí pé, “Àwa wá láti dè ọ́, kí a sì fi ọ́ lé àwọn Filistini lọ́wọ́.” Samsoni wí pé, “Ẹ búra fún mi pé, ẹ̀yin kì yóò fúnra yín pa mí.”
13 Ilia da bu adole i, “Defea! Ninia da di la: gili ilima imunu amo fawane. Be ninia da di hame medole legemu.” Amaiba: le, ilia da Sa: masane efe gaheabolo aduna amoga la: gili, magufu gelabo fisili, Lihi moilaiga oule asi.
“Àwa gbà,” ni ìdáhùn wọn. “Àwa yóò kàn dè ọ́, àwa yóò sì fi ọ́ lé wọn lọ́wọ́, àwa kì yóò pa ọ́.” Wọ́n sì dé pẹ̀lú okùn tuntun méjì, wọ́n sì mú u jáde wá láti ihò àpáta náà.
14 E da Lihi sogega doaga: musa: , logoba: le ahoanu, Filisidini da e gagumusa: bululusa doagala: i. E da hedolowane, Hina Gode Ea gasa bagade lai dagoi. Gasa bagade efe ea lobo la: gisu amo e da dadamunisi. La: gisu da gobia ha: i amo laluga nei dagoi agoane ba: i.
Bí ó ti súnmọ́ Lehi, àwọn Filistini ń pariwo bí wọ́n ṣe ń tò bọ̀. Ẹ̀mí Olúwa bà lé e pẹ̀lú agbára. Àwọn okùn ọwọ́ rẹ̀ dàbí òwú tí ó jóná, ìdè ọwọ́ rẹ̀ já kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.
15 Amalalu, e da dougi ayawane bogoi, ea magado gasa ba: i. E da amo gaguia gadole, amoga dunu 1,000 medole legei.
Nígbà tí ó rí egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tuntun kan, ó mú un, ó sì fi pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.
16 Amaiba: le, Sa: masane da amane gesami hea: i, “Na da dougi ea magado gasa amoga dunu 1,000 medole legei. Dougi ea magado gasa amoga na da dunu bagohame medole, ili bogoi da: i hodo amoga gagadole bi baheda: i bagohame hamosu.”
Samsoni sì wí pé, “Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo sọ wọ́n di òkìtì kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo ti pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.”
17 Amalalu, e da dougi magado gasa ha: digi dagoi. Ilia da amo hou doaga: i sogebi amoma Lamade Lihi dio asuli.
Nígbà tí ó dákẹ́ ọ̀rọ̀ í sọ, ó ju egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ náà nù, wọ́n sì pe ibẹ̀ ní Ramati-Lehi (ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ pa).
18 Amalalu, Sa: masane da hano bagade hanai ba: i. E da Hina Godema amane wele sia: su, “Di da fidibiba: le, na da baligiliwane hasalasi. Be wali na da hano hanaiba: le bogomu galebe, amola hame lalegagui Filisidini dunu ilia da na gagulaligimu amo da defeala: ?”
Nítorí tí òǹgbẹ gbẹ ẹ́ gidigidi, ó ké pe Olúwa, wí pé, “Ìwọ ti fún ìránṣẹ́ ní ìṣẹ́gun tí ó tóbi yìí. Ṣé èmi yóò ha kú pẹ̀lú òǹgbẹ, kí èmi sì ṣubú sí ọwọ́ àwọn aláìkọlà ènìyàn?”
19 Amalalu, Gode da Lihi sogega hano osobo hagudu dialu amo doasili, hano da heda: lebe ba: i. Sa: masane da amo hano nanu, bu uhibi ba: i. Amaiba: le, ilia da amo hano amoma Hagole (bai da ‘wele sia: su’) dio asuli. Amo hano da wali Lihi sogega diala.
Nígbà náà ni Ọlọ́run la kòtò ìsun omi tí ó wà ní Lehi, omi sì tú jáde láti inú rẹ̀. Nígbà tí Samsoni mú mi tan, agbára rẹ̀ sì padà, ọkàn sì sọjí, fún ìdí èyí wọ́n pe ìsun omi náà ni. Ẹni Hakkore (orísun ẹni tí ó pe Ọlọ́run) èyí tí ó sì wà ní Lehi di òní.
20 Filisidini dunu da Isala: ili soge ouligisu. Be ode 20 amoga, Isala: ili dunu da Sa: masane ema fa: no bobogei.
Samsoni ṣe ìdájọ́ Israẹli fún ogún ọdún ní àkókò àwọn ará Filistini.