< Bisisu 11 >

1 Yefeda da mae beda: iwane gasa bagade dadi gagui dunu esalu. E da Gilia: de sogega esalu. Ea ame da wadela: i hamosu uda (ea da: i hodo bidi lasu uda). Ea ada dio da Gilia: de.
Jefta ará Gileadi jẹ́ akọni jagunjagun. Gileadi ni baba rẹ̀; ṣùgbọ́n ìyá rẹ̀ jẹ́ panṣágà.
2 Gilia: de da dunu mano eno esalu. Ilia da ea udadafa amoga lalelegei. Ilia da asigilaloba, Yefeda amo ilia diasuga sefasi. Ilia da ema amane sia: i, “Di da ninia ada ea nana liligi hame lamu. Bai di da wamomano. Di da uda eno ea mano.”
Ìyàwó Gileadi sì bí àwọn ọmọkùnrin fún un, nígbà tí àwọn ọmọkùnrin wọ̀nyí dàgbà, wọ́n rán Jefta jáde kúrò nílé, wọ́n wí pé, “Ìwọ kì yóò ní ogún kankan ní ìdílé wa, nítorí pé ìwọ jẹ́ ọmọ obìnrin mìíràn.”
3 Yefeda da yolali ilima hobeale, Dobe soge ganodini esalu. Amogawi, udigili esalebe dunu eno da ema gilisili, ilia da gilisili lalu.
Jefta sì sá kúrò lọ́dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀, ó sì pàgọ́ sí ilẹ̀ Tobu, ó sì ń gbé níbẹ̀, níbẹ̀ ni àwọn ènìyàn kan ti ń tẹ òfin lójú parapọ̀ láti máa tẹ̀lé e kiri.
4 Amo fa: no, A:mounaide dunu da Isala: ili dunuma gegemusa: misi.
Ní àsìkò kan, nígbà tí àwọn ará Ammoni dìde ogun sí àwọn Israẹli,
5 Amo hou da doaga: beba: le, Gilia: de soge ouligisu dunu da Yefeda bu oule misa: ne, Dobe sogega asi.
Ó sì ṣe nígbà tí àwọn Ammoni bá Israẹli jagun, àwọn àgbàgbà Gileadi tọ Jefta lọ láti pè é wá láti ilẹ̀ Tobu.
6 Ilia amane sia: i, “Ninia da A: mounaide dunu ilima noga: le gegemusa: gini, di da ninima bisili ilibi gaguma.”
Wọ́n wí fún Jefta wí pé, “Wá kí o sì jẹ́ olórí ogun wa kí a lè kọjú ogun sí àwọn ará Ammoni.”
7 Be Yefeda da bu adole i, “Dilia da nama bagadewane higabeba: le, na ada ea diasuga sefasi dagoi. Amaiba: le, dilia da wali se nababeba: le, abuliba: le nama misibala: ?”
Jefta sì wí fún àwọn àgbàgbà Gileadi pé, “Ṣé kì í ṣe pé ẹ kórìíra mi tí ẹ sì lé mi kúrò ní ilé baba mi? Kí ló dé tí ẹ fi tọ̀ mí wá báyìí nígbà tí ẹ wà nínú wàhálà?”
8 Ilia da Yefedama bu adole i, “Ninia da di da nini A: mounaide dunuma gegemusa: ouligimu amola Gilia: de dunu huluane ilima ouligisu esalumu, amo hanaiba: le, wali dima misi.”
Àwọn àgbà Gileadi sì wí fún Jefta pé, “Nítorí rẹ̀ ni àwa fi yípadà sí ọ báyìí: tẹ̀lé wa, kí a lè dojú ìjà kọ àwọn ará Ammoni, ìwọ yóò sì jẹ olórí wa àti gbogbo àwa tí ń gbé ní Gileadi.”
9 Yefeda da ilima amane sia: i, “Dilia da na amo na sogega A: mounaide dunu ilima gegemusa: oule ahoasea, amola Hina Gode da fidibiba: le, ninia da amo dunuma hasalasisia, na da dilima ouligisu dunu esalumu.”
Jefta sì wí fún àwọn àgbàgbà Gileadi pé, “Bí ẹ̀yin bá mú mi padà láti bá àwọn ará Ammoni jà àti tí Olúwa bá fi wọ́n lé mi lọ́wọ́: ṣe èmi yóò jẹ́ olórí yín nítòótọ́?”
10 Ilia da bu adole i, “Defea! Hina Gode ba: ma: ne, ninia da di, ninia ouligisu hamoma: ne ilegele sia: sa.”
Àwọn àgbàgbà Gileadi sì wí fún Jefta pé, “Àwa fi Olúwa ṣe ẹlẹ́rìí: àwa yóò ṣe ohunkóhun tí o bá wí.”
11 Amaiba: le, Yefeda da Gilia: de ouligisu dunu amo sigi asi. Ilia da Yefeda ilia ouligisu amo hamoi. Yefeda ea musa: sia: i, amo huluane e da Misiba moilai amo ganodini, Hina Gode nabima: ne, bu sia: i.
Jefta sì tẹ̀lé àwọn àgbàgbà Gileadi lọ, àwọn ènìyàn náà sì fi ṣe olórí àti ọ̀gágun wọn. Jefta sì tún sọ gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tí ó ti sọtẹ́lẹ̀ níwájú Olúwa ní Mispa.
12 Amalalu, Yefeda da sia: adole iasu dunu amo A: mone hina bagade ema asunasi. Ilia ema amane adole ba: i, “Di da abuliba: le ninima gegesala: ? Di da abuliba: le ninima gegemusa: ninia soge ganodini golili sa: i?”
Jefta sì rán àwọn oníṣẹ́ sí ọba àwọn ará Ammoni pé, “Kí ni ẹ̀sùn tí o ní sí wa láti fi kàn wá tí ìwọ fi dojú ìjà kọ ilẹ̀ wa?”
13 A: mounaide hina bagade da Yefeda ea asunasi adole iasu dunuma bu adole i, “Isala: ili dunu da Idibidi soge fisili, ga asili, ilia da na soge amo ea defei da Anone Hano asili Ya: boge Hano amola Yodane Hano amoga doaga: i, amo soge Isala: ili dunu da wamolai. Dilia amo soge bu mae gegenane, nama bu ima.”
Ọba àwọn Ammoni dá àwọn oníṣẹ́ Jefta lóhùn pé, “Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli jáde ti Ejibiti wá. Wọ́n gba ilẹ̀ mi láti Arnoni dé Jabbok, àní dé Jordani, nítorí náà dá wọn padà lọ ní àlàáfíà àti ní pẹ̀lẹ́ kùtù.”
14 Be Yefeda da eno adole iasu dunu A: mounaide hina bagade ema asunasi.
Jefta sì tún ránṣẹ́ padà sí ọba àwọn ará Ammoni
15 Ilia da ema amane sia: i, “Dia sia: i amo Isala: ili dunu da Moua: be soge amola A: mone soge wamolai da ogogosa.
ó sì wí fún un pé, “Báyìí ni Jefta wí: àwọn ọmọ Israẹli kò gba ilẹ̀ Moabu tàbí ilẹ̀ àwọn ará Ammoni.
16 Hou da agoane ba: i. Isala: ili dunu da Idibidi soge fisili, ilia da hafoga: i wadela: i soge amo ganodini asili, Maga: me Hano Wayabo amoga doaga: i. Asili, ilia da Ga: idese sogega doaga: i.
Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n jáde kúrò ní Ejibiti àwọn ọmọ Israẹli la aginjù kọjá lọ sí ọ̀nà Òkun Pupa wọ́n sì lọ sí Kadeṣi.
17 Amalalu, ilia da Idome hina bagade ema sia: adola masa: ne dunu asunasi. Ilia da Isala: ili dunu da ea soge amoga golili sa: ili baligimusa: adole ba: i. Be Idome hina bagade da ilia sia: hame nabi. Amalalu, ilia da Moua: be hina bagade amane adole ba: i. Be e amola da ilia logo ga: i dagoi. Amaiba: le, Isala: ili dunu da Ga: idese amoga bu esalu.
Nígbà náà Israẹli rán àwọn oníṣẹ́ sí ọba Edomu pé, ‘Gbà fún wa láti gba ilẹ̀ rẹ̀ kọjá,’ ṣùgbọ́n ọba Edomu kò fetí sí wọn. Wọ́n tún ránṣẹ́ sí ọba Moabu bákan náà òun náà kọ̀. Nítorí náà Israẹli dúró sí Kadeṣi.
18 Amalalu, ilia da wadela: i hafoga: i soge amo ganodini bu ahoanu, ilia da Idome soge amola Moua: be soge mae golili sa: ili, la: ididili asili, ilia da Anone Hano na: iyadodili (Moua: be soge amo eso mabe la: idiga diala) amoga doaga: i. Ilia da amoga abula moilai gaguli esalu be Anone Hano hame degei. Bai amo hano da Moua: be soge ea eso mabe defei galu.
“Wọ́n rin aginjù kọjá, wọ́n pẹ́ àwọn ilẹ̀ Edomu àti ti Moabu sílẹ̀, nígbà tí wọ́n gba apá ìlà-oòrùn Moabu, wọ́n sì tẹ̀dó sí apá kejì Arnoni. Wọn kò wọ ilẹ̀ Moabu, nítorí pé ààlà rẹ̀ ni Arnoni wà.
19 Amalalu, Isala: ili dunu da A: moulaide hina bagade Hesiabone moilai bai bagade ganodini esalu ea dio amo Saihone ema sia: adola ahoasu dunu asunasi. Ilia da ilia soge amoga doaga: musa: , ea soge golili sa: ili, baligimusa: adole ba: i.
“Nígbà náà ni Israẹli rán àwọn oníṣẹ́ sí Sihoni ọba àwọn ará Amori, ẹni tí ń ṣe àkóso ní Heṣboni, wọ́n sì wí fún un pé, ‘Jẹ́ kí a la ilẹ̀ rẹ kọjá lọ sí ibùgbé wa.’
20 Be Saihone da “hame mabu” sia: i. E da ea dadi gagui dunu huluane gilisili, Ya: iha: se sogega fiafiale fi. Amalalu, e da Isala: ili dunuma doagala: i.
Ṣùgbọ́n Sihoni kò gba Israẹli gbọ́ (kò fọkàn tán an) láti jẹ́ kí ó kọjá. Ó kó gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ jọ, ó sì tẹ̀dó sí Jahisa láti bá Israẹli jagun.
21 Be Isala: ili ilia Hina Gode da fidibiba: le, ilia da Saihone amola ea dadi gagui dunu hasali. Amalalu, Isala: ili dunu da A: moulaide dunu huluane amo sogega esalu ilia soge huluane lai dagoi.
“Olúwa Ọlọ́run Israẹli sì fi Sihoni àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ lé Israẹli lọ́wọ́, wọ́n sì ṣẹ́gun wọn. Israẹli sì gba gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Amori tí wọ́n ń gbé ní agbègbè náà,
22 Ilia da A: moulaide soge huluane gesowale fi. Soge defei da gagoe (south) Anone Hano amola gagoe (north) da Ya: boge Hano. Eso mabadili alalo da hafoga: i wadela: i soge amola eso dabe la: idi alalo da Yodane Hano.
wọ́n gbà gbogbo agbègbè àwọn ará Amori, láti Arnoni tí ó fi dé Jabbok, àti láti aginjù dé Jordani.
23 Amaiba: le, Hina Gode Hisu da Ea fi dunu (Isala: ili fi) amo soge ili gesowale fima: ne, A:moulaide dunu sefasi dagoi.
“Wàyí o, nígbà tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti lé àwọn ará Amori kúrò níwájú àwọn ènìyàn rẹ̀; Israẹli, ẹ̀tọ́ wo ni ẹ ní láti gba ilẹ̀ náà?
24 Di da amo soge bu samogema: bela: ? Hame mabu! Dia ‘gode’ liligi amo Gimose da soge dilima i, amo dia gagumu da defea. Be liligi amola soge huluane amo ninia Hina Gode da ninima i, amo huluane ninia da gagumu.
Ǹjẹ́ ìwọ kì yóò ha gba èyí tí Kemoṣi òrìṣà rẹ fi fún ọ? Bákan náà àwa yóò gba èyíkéyìí tí Olúwa Ọlọ́run wa fi fún wa.
25 Moua: be hina bagade amo Bela: ge (Sibo egefe) e da Isala: ili fi ilima gegemusa: logebela: ? Hame mabu! E da eso afaega ninima gegebela: ? Hame mabu! Di da ea hou baligisa amo dawa: sala: ?
Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Balaki ọmọ Sippori, ọba Moabu lọ? Ǹjẹ́ òun ha ṣe gbólóhùn asọ̀ pẹ̀lú Israẹli bí? Tàbí òun dojú ìjà kọ wọ́n rí bí?
26 Isala: ili dunu da ode 300 amoga Hesiabone, Aloue amola eno moilai amo sisiga: sa moilai Anone Hano bega: diala, amo ganodini esalu. Di da abuliba: le amo ode ganodini amo soge bu hame samogebela: ?
Fún ọ̀ọ́dúnrún ọdún ni Israẹli fi ṣe àtìpó ní Heṣboni, Aroeri àti àwọn ìgbèríko àti àwọn ìlú tí ó yí Arnoni ká. Èéṣe tí ìwọ kò fi gbà wọ́n padà ní àsìkò náà?
27 Hame mabu! Na da dima wadela: le hame hamoi. Di da nama gegemusa: dawa: beba: le, wadela: le hamosa. Hina Gode Hisu da fofada: su dunu. E da wali eso Isala: ili dunu da moloi o A: mounaide dunu da moloi, Hi fawane da sia: mu.”
Èmi kọ́ ni ó ṣẹ̀ ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ ni ó ṣẹ̀ mí nípa kíkógun tọ̀ mí wá. Jẹ́ kí Olúwa olùdájọ́, ṣe ìdájọ́ lónìí láàrín àwọn ọmọ Israẹli àti àwọn ará Ammoni.”
28 Be A: mounaide hina bagade da Yefeda ea adole iasisu amo hame nabi.
Ṣùgbọ́n ọba àwọn Ammoni kò fetí sí iṣẹ́ tí Jefta rán sí i.
29 Amalalu, Hina Gode Ea A: silibu da Yefeda amoma aligila sa: i. E da asili, Gilia: de soge amola Mana: se soge baligili, Misiba moilai (Gilia: de soge ganodini) amoga buhagi. Amalalu, e da A: mone sogega asi.
Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé Jefta òun sì la Gileadi àti Manase kọjá. Ó la Mispa àti Gileadi kọjá láti ibẹ̀, ó tẹ̀síwájú láti bá àwọn ará Ammoni jà.
30 E da Hina Godema amane sia: i, “Dia fidimuba: le, na da A: mounaide dunu fane legesea,
Jefta sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa pé, “Bí ìwọ bá fi àwọn ará Ammoni lé mi lọ́wọ́,
31 na da na diasuga bu masea, adi liligi nama yosia: musa: na diasu logoga masea, na da amo Dima gobele salasu hamoma: ne gobele salimu.”
yóò sì ṣe, ohunkóhun tí ó bá jáde láti ẹnu-ọ̀nà ilé mi láti wá pàdé mi, nígbà tí èmi bá ń padà bọ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Ammoni ní àlàáfíà, yóò jẹ́ ti Olúwa, èmi yóò sì fi rú ẹbọ bí ọrẹ ẹbọ sísun.”
32 Amalalu, Yefeda da A: mounaide dunuma gegemusa: , hano degei dagoi. Amola Hina Gode da fidibiba: le, e da A: mounaide dunu hasali dagoi.
Jefta sì jáde lọ láti bá àwọn ará Ammoni jagun, Olúwa sì fi wọ́n lé e lọ́wọ́.
33 E da ilima doagala: i. E da Aloue moilai amola soge amo da Minidi moilai sisiga: i, amola moilai bai bagade huluane da20amoma doagala: le, A:mounaide dunu sefasili, A:ibele Gelamimi moilai bai bagadega doaga: i. Isala: ili dunu da A: mounaide dunu hasali amola ilia da A: mounaide dunu osea: i medole legei.
Òun sì ṣẹ́gun wọn, ó sì pa wọ́n ní à pa tán láti Aroeri títí dé agbègbè Minniti, ó jẹ́ ogún ìlú, títí dé Abeli-Keramimu. Báyìí ni Israẹli ti ṣẹ́gun àwọn ará Ammoni.
34 Yefeda da Misiba moilaiga buhagili, idiwi da ilibu dusa amola gagafola, hahawane ema yosia: musa: manebe ba: i. E da ea mano afadafa fawane esalu.
Nígbà tí Jefta padà sí ilé rẹ̀ ní Mispa, wò ó, ọmọ rẹ̀ obìnrin ń jáde bọ̀ wá pàdé rẹ̀ pẹ̀lú timbrili àti ijó. Òun ni ọmọ kan ṣoṣo tí ó ní: kò ní ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin mìíràn yàtọ̀ sí òun nìkan.
35 Yefeda da idiwi ba: beba: le, se bagade nabi. E da ea abula gadelale, amane sia: i, “Nadiwi! Na da diba: le se bagadedafa naba! Bai na da Hina Godema dafawane hamomusa: ilegele sia: i dagoiba: le, bu afadenemu da hamedei galebe.”
Ní ìgbà tí ó rí i ó fa aṣọ rẹ̀ ya ní ìbànújẹ́, ó sì ké wí pé, “Háà! Ọ̀dọ́mọbìnrin mi, ìwọ fún mi ní ìbànújẹ́ ọkàn ìwọ sì rẹ̀ mí sílẹ̀ gidigidi, nítorí pé èmi ti ya ẹnu mi sí Olúwa ní ẹ̀jẹ́, èmi kò sì le sẹ́ ẹ̀jẹ́ mi.”
36 Idiwi da ema bu adole i, “Na ada! Di da Hina Godema amane hamoma: ne ilegele sia: i dagoi. Hina Gode da dia ha lai dunu amo A: mounaide dunu amo fane legei dagoi. Amaiba: le, di da dia musa: Godema sia: i amo hou nama hamomu da defea.
Ọmọ náà sì dáhùn pé, “Baba mi bí ìwọ bá ti jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa, ṣe sí mi gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ, ní báyìí tí Olúwa ti gba ẹ̀san fún ọ lára àwọn ọ̀tá rẹ, àwọn ará Ammoni.
37 Be na da liligi afadafa dima edegesa. Na da oubi aduna amoga agolo soge ganodini ahoanumu amola na na: iyado huluane gilisili dimu da defeala: ? Bai na da dunuma hamedafa fimu.”
Ṣùgbọ́n yọ̀ǹda ìbéèrè kan yìí fún mi, gbà mí láààyè oṣù méjì láti rìn ká orí àwọn òkè, kí n sọkún pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ mi torí mo jẹ́ wúńdíá tí n kò sì ní lè ṣe ìgbéyàwó.”
38 Yefeda da amane sia: i, “Defea! Di masa! Oubi aduna amoga agoane hamoma.” Amalalu, e amola ea na: iyado a: fini eno ilia da agolo sogega asili, dinanu. Bai e da dunuga mae lale, mano mae lalelegele bogomu dawa: beba: le dinanu.
Jefta dá lóhùn pé, “Ìwọ lè lọ.” Ó sì gbà á láààyè láti lọ fún oṣù méjì. Òun àti àwọn ọmọbìnrin yòókù lọ sí orí àwọn òkè, wọ́n sọkún nítorí pé kì yóò lè ṣe ìgbéyàwó.
39 Oubi aduna uduli, e da ea ada ema buhagili, ea eda e Hina Godema ilegele sia: i defele ema hamoi dagoi. Yefeda idiwi da dunuma gilisili mae golale bogoi. Isala: ili dunu da amo dawa: beba: le, agoane hou hamonana.
Lẹ́yìn oṣù méjì náà, ó padà tọ baba rẹ̀ wá òun sì ṣe sí i bí ẹ̀jẹ́ tí ó ti jẹ́. Ọmọ náà sì jẹ́ wúńdíá tí kò mọ ọkùnrin rí. Èyí sì bẹ̀rẹ̀ àṣà kan ní Israẹli
40 Ode huluane ganodini, Isala: ili a: fini huluane da sogega asili, eso biyadu amoga Yefeda (Gilia: de dunu) ea idiwi amo dawa: le, dinana.
wí pé ní ọjọ́ mẹ́rin láàrín ọdún àwọn obìnrin Israẹli a máa lọ láti ṣọ̀fọ̀ àti ṣe ìrántí ọmọbìnrin Jefta ti Gileadi.

< Bisisu 11 >